2 Samuel 23
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Wọ̀nyí sì ni ọ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi.
1 Ora, estas são as últimas palavras de Davi. Davi, o filho de Jessé, disse; e o homem que foi exaltado às alturas, o ungido do Deus de Jacó, e o doce salmista de Israel, disse:
2 “Ẹ̀mí Olúwa sọ ọ̀rọ̀ nípa mi,
2 O Espírito do SENHOR falou por mim, e a sua palavra estava na minha língua.
3 Ọlọ́run Israẹli ni,
3 O Deus de Israel disse, a Rocha de Israel falou comigo: Aquele que rege sobre os homens precisa ser justo, regendo no temor de Deus.
4 Yóò sì dàbí ìmọ́lẹ̀ òwúrọ̀ nígbà tí oòrùn bá là,
4 E ele será como a luz da manhã, quando o sol se levanta, uma manhã sem nuvens; como a relva tenra que brota da terra através do brilho claro depois da chuva.
5 “Lóòtítọ́ ilé mi kò rí bẹ́ẹ̀ níwájú Ọlọ́run,
5 Embora a minha casa não esteja assim com Deus; ele fez comigo um pacto eterno, ordenado em todas as coisas, e seguro; pois esta é toda a minha salvação, e todo o meu desejo, mesmo que ele não o faça crescer.
6 Ṣùgbọ́n gbogbo àwọn ọmọ Beliali yóò dàbí ẹ̀gún ẹ̀wọ̀n tí a ṣá tì,
6 Porém, todos os filhos de Belial serão como espinhos lançados fora, porque não podem ser pegos com mãos;
7 Ṣùgbọ́n ọkùnrin tí yóò tọ́ wọn yóò
7 mas o homem que neles tocar deve estar cercado com ferro e com haste de uma lança; e eles serão completamente queimados com fogo no mesmo lugar.
8 Wọ̀nyí sì ni orúkọ àwọn akọni ọkùnrin tí Dafidi ní:
8 Estes são os nomes dos homens valentes que Davi tinha: O taquemonita que se assentava no assento, chefe entre os capitães; o mesmo era Adino, o eznita; ele levantou a sua lança contra oitocentos, os quais matou de uma única vez.
9 Ẹni tí ó tẹ̀lé e ni Eleasari ọmọ Dodo ará Ahohi, ọ̀kan nínú àwọn alágbára ọkùnrin mẹ́ta ti ó wà pẹ̀lú Dafidi, nígbà tí wọ́n pe àwọn Filistini ní ìjà, àwọn ọkùnrin Israẹli sì ti lọ kúrò.
9 E depois dele vinha Eleazar, o filho de Dodô, o aoíta, um dos três valentes com Davi, quando eles desafiaram os filisteus que estavam lá reunidos para a batalha, e os homens de Israel fugiram;
10 Òun sì dìde, ó sì kọlu àwọn Filistini títí ọwọ́ fi kún un, ọwọ́ rẹ̀ sì lẹ̀ mọ́ idà; Olúwa sì ṣiṣẹ́ ìgbàlà ńlá lọ́jọ́ náà, àwọn ènìyàn sì padà bọ̀ lẹ́yìn rẹ̀ láti kó ìkógun.
10 ele se levantou, e feriu os filisteus até que a sua mão ficou exausta, e a sua mão ficou presa à espada; e o SENHOR operou uma grande vitória naquele dia; e o povo retornou depois dele somente para despojar.
11 Ẹni tí ó tẹ̀lé e ni Ṣamma ọmọ Agee ará Harari, àwọn Filistini sì kó ara wọn jọ láti piyẹ́, oko kan sì wà níbẹ̀ tí ó kún fun lẹntili, àwọn ọmọ-ogun Israẹli sì sá kúrò níwájú àwọn Filistini.
11 E, depois dele vinha Samá, o filho de Agé, o haratita. E os filisteus estavam reunidos em tropa, onde havia um pedaço de terra cheio de lentilhas; e o povo fugiu dos filisteus.
12 Ṣamma sì dúró láàrín méjì ilẹ̀ náà, ó sì gbà á sílẹ̀, ó sì pa àwọn Filistini Olúwa sì ṣe ìgbàlà ńlá.
12 Ele, porém, pôs-se de pé no meio do terreno, e o defendeu, e matou os filisteus; e o SENHOR operou uma grande vitória.
13 Mẹ́ta nínú àwọn ọgbọ̀n ìjòyè sọ̀kalẹ̀, wọ́n sì tọ Dafidi wá ní àkókò ìkórè nínú ihò Adullamu, ọ̀wọ́ àwọn Filistini sì dó sí àfonífojì Refaimu.
13 E três dos trinta chefes desceram, e vieram até Davi na época da colheita à caverna de Adulão; e a tropa dos filisteus acampou no vale de Refaim.
14 Dafidi sì wà nínú odi, ibùdó àwọn Filistini sì wà ní Bẹtilẹhẹmu nígbà náà.
14 E Davi estava, então, em uma fortaleza, e a guarnição dos filisteus estava, naquele tempo, em Belém.
15 Dafidi sì ń pòǹgbẹ, ó wí báyìí pé, “Ta ni yóò fún mi mu nínú omí kànga tí ń bẹ ní Bẹtilẹhẹmu, èyí tí ó wà ní ìhà ẹnu-bodè.”
15 E Davi ansiava, e disse: Ah, se alguém me desse de beber das águas do poço de Belém, que fica junto ao portão!
16 Àwọn ọkùnrin alágbára mẹ́ta sì la ogún àwọn Filistini lọ, wọ́n sì fa omi láti inú kànga Bẹtilẹhẹmu wá, èyí tí ó wà ní ìhà ẹnu-bodè, wọ́n sì mú tọ Dafidi wá, òun kò sì fẹ́ mu nínú rẹ̀, ṣùgbọ́n ó tú u sílẹ̀ fún Olúwa.
16 E os três homens valentes irromperam pelo exército dos filisteus, e retiraram água do poço de Belém, que ficava junto ao portão, e a tomaram e trouxeram até Davi; todavia ele não quis beber dela, mas derramou-a ao SENHOR.
17 Òun sì wí pé, “Kí a má rí, Olúwa, tí èmi ó fi ṣe èyí; ṣé èyí ni ẹ̀jẹ̀ àwọn ọkùnrin tí ó lọ tí àwọn tí ẹ̀mí wọn lọ́wọ́?” Nítorí náà òun kò sì fẹ́ mú un.
17 E ele disse: Esteja longe de mim, ó SENHOR, que eu faça isto; não é este o sangue dos homens que foram arriscar as suas vidas? Por isto ele não quis bebê-la. Estas coisas fizeram estes três homens valentes.
18 Abiṣai, arákùnrin Joabu, ọmọ Seruiah, òun náà ni pàtàkì nínú àwọn mẹ́ta. Òun ni ó sì gbé ọ̀kọ̀ rẹ̀ sókè sí ọ̀ọ́dúnrún (300) ènìyàn, ó sì pa wọ́n, ó sì ní orúkọ nínú àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta.
18 E Abisai, o irmão de Joabe, o filho de Zeruia, era chefe entre os três. E ele levantou a sua lança contra trezentos, e os matou, e teve o nome entre os três.
19 Ọlọ́lá jùlọ ni òun jẹ́ nínú àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta, ó sì jẹ́ olórí fún wọn, ṣùgbọ́n òun kò tó àwọn mẹ́ta ìṣáájú.
19 Não foi ele o mais honorável dos três? Portanto, ele era o capitão deles; todavia não alcançou os três primeiros.
20 Benaiah, ọmọ Jehoiada, ọmọ akọni ọkùnrin kan tí Kabṣeeli, ẹni tí ó pọ̀ ní iṣẹ́ agbára, òun pa àwọn ọmọ Arieli méjì ti Moabu; ó sọ̀kalẹ̀ pẹ̀lú ó sì pa kìnnìún kan nínú ihò lákoko òjò-dídì.
20 E Benaia, o filho de Joiada, o filho de um homem valente, de Cabzeel, que havia feito muitos atos, ele matou dois homens de Moabe semelhantes a leões; também desceu e matou um leão no meio de uma cova, no tempo da neve.
21 Ó sì pa ará Ejibiti kan, ọkùnrin tí ó dára láti wò, ará Ejibiti náà sì ní ọ̀kọ̀ kan ní ọwọ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n Benaiah sì sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ọ́ lọ, pẹ̀lú ọ̀pá ní ọwọ́, ó sì gba ọ̀kọ̀ náà lọ́wọ́ ará Ejibiti náà, ó sì fi ọ̀kọ̀ rẹ̀ pa á.
21 E ele matou um egípcio, um homem formoso; e o egípcio tinha uma lança em sua mão; mas ele desceu até ele com uma vara, e arrancou a lança da mão do egípcio, e o matou com a sua própria lança.
22 Nǹkan wọ̀nyí ní Benaiah ọmọ Jehoiada ṣe, ó sì ní orúkọ nínú àwọn ọkùnrin alágbára mẹ́ta náà.
22 Estas coisas fez Benaia, o filho de Joiada, e teve o nome entre os três homens valentes.
23 Nínú àwọn ọgbọ̀n náà, òun ní ọlá jùlọ, ṣùgbọ́n òun kò tó àwọn mẹ́ta ti ìṣáájú. Dafidi sì fi í ṣe ìgbìmọ̀ rẹ̀.
23 Ele foi mais honorável do que os trinta, mas não alcançou os três primeiros. E Davi o pôs sobre a sua guarda.
24 Ọ̀kan nínú àwọn ọgbọ̀n náà:
24 Asael, o irmão de Joabe, era um dos trinta; Elanã, o filho de Dodô de Belém;
25 Ṣamma ará Haroditi,
25 Samá, o harodita, Elica, o harodita;
26 Helesi ará Palti,
26 Heles, o paltita; Ira, filho de Iques, o tecoíta;
27 Abieseri ará Anatoti,
27 Abiezer, o anatotita; Mebunai, o husatita;
28 Salmoni ará Ahohi,
28 Zalmom, o aoíta; Maarai, o netofatita;
29 Heledi ọmọ Baanah, ará Netofa,
29 Helebe, o filho de Baana, o netofatita; Itai, o filho de Ribai, de Gibeá, dos filhos de Benjamim;
30 Benaiah ará Piratoni,
30 Benaia, o piratonita; Hidai, dos ribeiros de Gaás;
31 Abi-Alboni ará Arbati,
31 Abi-Albom, o arbatita; Azmavete, o barumita;
32 Eliaba ará Ṣaalboni,
32 Eliaba, o saalbonita, dos filhos de Jasém, Jônatas;
33 ọmọ Ṣamma ará Harari,
33 Samá, o hararita; Aião, filho de Sarar, o ararita;
34 Elifeleti ọmọ Ahasbai, ọmọ ará Maakati,
34 Elifelete, o filho de Aasbai, filho do maacatita; Eliã, o filho de Aitofel, o gilonita;
35 Hesro ará Karmeli,
35 Hezrai, o carmelita; Paarai, o arbita;
36 Igali ọmọ Natani ti Soba,
36 Igal, o filho de Natã, de Zobá; Bani, o gadita;
37 Seleki ará Ammoni,
37 Zeleque, o amonita; Naarai, o beerotita, o escudeiro de Joabe, o filho de Zeruia;
38 Ira ará Itri,
38 Ira, um jetrita; Garebe, um jetrita;
39 Uriah ará Hiti.
39 Urias, o heteu: trinta e sete ao todo.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Samuel 23, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.