2 Samuel 13
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ó sì ṣe, lẹ́yìn èyí, Absalomu ọmọ Dafidi ní àbúrò obìnrin kan tí ó ṣe arẹwà, orúkọ rẹ̀ a sì máa jẹ́ Tamari; Amnoni ọmọ Dafidi sì fẹ́ràn rẹ̀.
1 E sucedeu depois disso, que Absalão, o filho de Davi, tinha uma irmã formosa, cujo nome era Tamar; e Amnon, o filho de Davi, a amava.
2 Amnoni sì banújẹ́ títí ó fi ṣe àìsàn nítorí Tamari àbúrò rẹ̀ obìnrin; nítorí pé wúńdíá ni; ó sì ṣe ohun tí ó ṣòro lójú Amnoni láti bá a dàpọ̀.
2 E Amnom ficou tão atormentado que caiu enfermo por causa da sua irmã Tamar; porquanto ela era virgem; e Amnom considerava difícil para ele fazer algo a ela.
3 Ṣùgbọ́n Amnoni ní ọ̀rẹ́ kan, orúkọ rẹ̀ a sì máa jẹ́ Jonadabu, ọmọ Ṣimea ẹ̀gbọ́n Dafidi, Jonadabu sì jẹ́ alárékérekè ènìyàn gidigidi.
3 Amnom, porém, tinha um amigo, cujo nome era Jonadabe, o filho de Simeia, irmão de Davi; e Jonadabe era um homem mui sutil.
4 Ó sì wí fún un pé, “Èéṣe tí ìwọ ọmọ ọba ń fi ń rù lójoojúmọ́ báyìí? Ǹjẹ́ o kò ní sọ fún mi?”
4 E ele lhe disse: Por que estás tu, sendo o filho do rei, magro dia após dia? Não me contarás? E Amnon disse a ele: Eu amo Tamar, a irmã do meu irmão Absalão.
5 Jonadabu sì wí fún un pé, “Dùbúlẹ̀ ní ibùsùn rẹ kí ìwọ sì díbọ́n pé, ìwọ kò sàn, baba rẹ yóò sì wá wò ọ́, ìwọ ó sì wí fún un pé, ‘Jọ̀wọ́ jẹ́ kí Tamari àbúrò mi wá kí ó sì fún mi ní oúnjẹ kí ó sì ṣe oúnjẹ náà níwájú mi kí èmi ó rí i, èmi ó sì jẹ ẹ́ ní ọwọ́ rẹ̀.’ ”
5 E Jonadabe disse a ele: Deita-te na tua cama, e faz-te de enfermo; e quando o teu pai vier para te ver, diz a ele: Rogo-te que deixes Tamar, a minha irmã, vir e me dar alimento, e preparar a carne à minha vista, para que eu possa vê-la, e comer da sua mão.
6 Amnoni sì dùbúlẹ̀, ó sì díbọ́n pé òun ṣàìsàn, ọba sì wá wò ó, Amnoni sì wí fún ọba pé, “Jọ̀wọ́, jẹ́ kí Tamari àbúrò mi ó wá, kí ó sì dín àkàrà méjì lójú mi, èmi ó sì jẹ ní ọwọ́ rẹ̀.”
6 Assim, Amnom se deitou, e se fez de enfermo; e quando o rei veio para o ver, Amnom disse ao rei: Rogo-te que deixes Tamar, minha irmã, vir fazer dois bolos à minha vista, para que eu possa comer da sua mão.
7 Dafidi sì ránṣẹ́ sí Tamari ní ilé pé, “Lọ sí ilé Amnoni ẹ̀gbọ́n rẹ, kí ó sì se oúnjẹ fún un.”
7 Então, Davi enviou à casa, a Tamar, dizendo: Vai agora até a casa do teu irmão Amnom e prepara alimento para ele.
8 Tamari sì lọ sí ilé Amnoni ẹ̀gbọ́n rẹ̀, òun sì ń bẹ ní ìdùbúlẹ̀. Tamari sì mú ìyẹ̀fun, ó sì pò ó, ó sì fi ṣe àkàrà lójú rẹ̀, ó sì dín àkàrà náà.
8 Assim, Tamar foi à casa do seu irmão Amnom; e ele estava deitado. E ela tomou farinha, e a amassou, e fez bolos à vista dele, e assou os bolos.
9 Òun sì mú àwo náà, ó sì dà á sínú àwo mìíràn níwájú rẹ̀; ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti jẹ.
9 E ela pegou uma panela, e os colocou diante dele; mas ele se recusou a comê-los. E Amnon disse: Retirai de mim todos os homens. E se retiraram todos os homens de diante dele.
10 Amnoni sì wí fún Tamari pé, “Mú oúnjẹ náà wá sí yàrá, èmi ó sì jẹ ẹ́ lọ́wọ́ rẹ.” Tamari sì mú àkàrà tí ó ṣe, ó sì mú un tọ Amnoni ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ní yàrá.
10 E Amnom disse a Tamar: Trazei o alimento à câmara, para que eu possa comer da tua mão. E Tamar tomou os bolos que ela havia feito, e os trouxe à câmara para Amnom, o seu irmão.
11 Nígbà tí ó sì súnmọ́ ọn láti fi oúnjẹ fún un, òun sì dìímú, ó sì wí fún un pé, “Wá dùbúlẹ̀ tì mí, àbúrò mi.”
11 E, quando ela os trouxe para ele comer, ele a agarrou e disse a ela: Vem te deitar comigo, minha irmã.
12 Òun sì dá a lóhùn wí pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́ ẹ̀gbọ́n mi, má ṣe tẹ́ mi; nítorí pé kò tọ kí a ṣe irú nǹkan bẹ́ẹ̀ ní Israẹli, ìwọ má ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí.
12 E ela respondeu: Não, meu irmão, não me forces; porque tal coisa não deve ser feita em Israel; não faças esta loucura.
13 Àti èmi, níbo ni èmi ó gbé ìtìjú mi wọ̀? Ìwọ ó sì dàbí ọ̀kan nínú àwọn aṣiwèrè ní Israẹli. Ǹjẹ́ nítorí náà, èmi bẹ̀ ọ́, sọ fún ọba; nítorí pé òun kì yóò kọ̀ láti fi mí fún ọ.”
13 E eu, para onde farei ir a minha vergonha? E, quanto a ti? Serás como um dos loucos de Israel. Agora, portanto, rogo-te, fala com o rei; porque ele não me negará a ti.
14 Ṣùgbọ́n ó kọ̀ láti gbọ́ ohùn rẹ̀; ó sì fi agbára mú un, ó sì ṣẹ́gun rẹ̀, ó sì bá a dàpọ̀.
14 Todavia, ele não quis atentar à sua voz; mas, sendo mais forte do que ela, forçou-a, e se deitou com ela.
15 Amnoni sì kórìíra rẹ̀ gidigidi, ìríra náà sì wá ju ìfẹ́ tí òun ti ní sí i rí lọ. Amnoni sì wí fún un pé, “Dìde, kí o sì máa lọ!”
15 Então, Amnom odiou-a sobremaneira; de tal forma que o ódio com o qual a odiou foi maior do que o amor com que a amou. E Amnom disse a ela: Levanta-te e vai-te.
16 Òun sì wí fún un pé, “Kó ha ní ìdí bí! Lílé tí ìwọ ń lé mi yìí burú ju èyí tí ìwọ ti ṣe sí mi lọ.”
16 E ela disse a ele: Não há motivo; este mal de me despedires é maior do que o outro que me fizeste. Ele, porém, não quis atentar a ela.
17 Òun sì pe ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ tí í ṣe ìránṣẹ́ rẹ̀, ó sì wí fún un pé, “Jọ̀wọ́, ti obìnrin yìí sóde fún mi, kí o sì ti ìlẹ̀kùn mọ́ ọn.”
17 Então, ele chamou o seu servo que lhe servia, e disse: Retira, agora, esta mulher da minha presença, e tranca a porta após ela.
18 Òun sì ní aṣọ aláràbarà kan lára rẹ̀, nítorí irú aṣọ àwọ̀lékè bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọbìnrin ọba tí í ṣe wúńdíá máa ń wọ̀. Ìránṣẹ́ rẹ̀ sì mú un jáde, ó sì ti ìlẹ̀kùn mọ́ ọn.
18 E ela trazia uma vestimenta de diversas cores sobre si; porque com tais túnicas eram vestidas as filhas do rei que eram virgens. Então, o seu servo a trouxe para fora, e trancou a porta após ela.
19 Tamari sì bu eérú sí orí rẹ̀, ó sì fa aṣọ aláràbarà tí ń bẹ lára rẹ̀ ya, ó sì ká ọwọ́ rẹ̀ lé orí, ó sì ń kígbe bí ó ti ń lọ.
19 E Tamar pôs cinzas sobre a sua cabeça, e rasgou a sua vestimenta de diversas cores que estava vestindo, e pôs sua mão sobre a cabeça, e seguiu chorando.
20 Absalomu ẹ̀gbọ́n rẹ̀ sì bí i léèrè pé, “Amnoni ẹ̀gbọ́n rẹ bá ọ sùn bí? Ǹjẹ́ àbúrò mi, dákẹ́; ẹ̀gbọ́n rẹ ní í ṣe; má fi nǹkan yìí sí ọkàn rẹ.” Tamari sì jókòó ní ìbànújẹ́ ní ilé Absalomu ẹ̀gbọ́n rẹ̀.
20 E Absalão, seu irmão, disse a ela: Amnom, teu irmão, esteve contigo? Mas segura, agora, a tua paz, minha irmã; ele é teu irmão; não te turbes com esta coisa. Assim, Tamar permaneceu desolada na casa do seu irmão Absalão.
21 Ṣùgbọ́n nígbà tí Dafidi ọba gbọ́ gbogbo nǹkan wọ̀nyí, inú rẹ̀ bàjẹ́ gidigidi.
21 Mas quando o rei Davi ouviu todas estas coisas, ficou mui irado.
22 Absalomu kò sì bá Amnoni sọ nǹkan rere, tàbí búburú, nítorí pé Absalomu kórìíra Amnoni nítorí èyí tí ó ṣe, àní tí ó fi agbára mú Tamari àbúrò rẹ̀.
22 E Absalão não falou nem bem, nem mal com o seu irmão Amnom; porque Absalão odiou Amnom, porquanto ele havia forçado sua irmã Tamar.
23 Ó sì ṣe, lẹ́yìn ọdún méjì, Absalomu sì ní olùrẹ́run àgùntàn ní Baali-Hasori, èyí tí ó gbé Efraimu, Absalomu sì pe gbogbo àwọn ọmọ ọba.
23 E sucedeu, depois de dois anos completos, que Absalão tinha tosquiadores de ovelhas em Baal-Hazor, que fica ao lado de Efraim; e Absalão convidou todos os filhos do rei.
24 Absalomu sì tọ ọba wá, ó sì wí pé, “Wò ó, jọ̀wọ́, ìránṣẹ́ rẹ ní olùrẹ́run àgùntàn, èmi bẹ̀ ọ́, jẹ́ kí ọba, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ bá ìránṣẹ́ rẹ lọ.”
24 E Absalão veio até o rei, e disse: Agora que o teu servo tem tosquiadores de ovelhas; suplico-te que o rei e os seus servos venham com o teu servo.
25 Ọba sì wí fún Absalomu pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ, ọmọ mi, mo bẹ̀ ọ́, má ṣe jẹ́ kí gbogbo wa lọ, kí a má bá à mú ọ náwó púpọ̀.” Ó sì rọ̀ ọ́ gidigidi, ṣùgbọ́n òun kò fẹ́ lọ, òun sì súre fún un.
25 E o rei disse a Absalão: Não, filho meu, não iremos todos de uma vez, para que não te sejamos por peso. E ele insistiu. Todavia, ele não quis ir, mas o abençoou.
26 Absalomu sì wí pé, “Bí kò bá le rí bẹ́ẹ̀, èmi bẹ̀ ọ́, jẹ́ kí Amnoni ẹ̀gbọ́n mi bá wa lọ.”
26 Então, disse Absalão: Se não, rogo-te, deixa que o meu irmão Amnom venha conosco. E o rei disse a ele: Por que ele deveria ir contigo?
27 Absalomu sì rọ̀ ọ́, òun sì jẹ́ kí Amnoni àti gbogbo àwọn ọmọ ọba bá a lọ.
27 Absalão, porém, insistiu com ele para que deixasse Amnom e todos os filhos do rei irem com ele.
28 Absalomu sì fi àṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Kí ẹ̀yin máa kíyèsi àkókò tí ọtí-wáinì yóò mú ọkàn Amnoni dùn, èmi ó sì wí fún yín pé, ‘Kọlu Amnoni,’ kí ẹ sì pa á. Ẹ má bẹ̀rù. Ṣé èmi ni ó fi àṣẹ fún yin? Ẹ ṣe gírí, kí ẹ ṣe bí alágbára ọmọ.”
28 Ora, Absalão havia ordenado aos seus servos, dizendo: Marcai, pois, quando o coração de Amnom estiver alegre com vinho, e quando eu vos disser: Feri Amnom; então matai-o, não temais; não vo-lo ordenei eu? Sede corajosos e sede valentes.
29 Àwọn ìránṣẹ́ Absalomu sì ṣe sí Amnoni gẹ́gẹ́ bí Absalomu ti pàṣẹ. Gbogbo àwọn ọmọ ọba sì dìde, olúkúlùkù gun ìbáaka rẹ̀, wọ́n sì sá.
29 E os servos de Absalão fizeram a Amnom segundo Absalão havia ordenado. Então, todos os filhos do rei se levantaram, e cada qual subiu sobre sua mula, e fugiu.
30 Nígbà tí wọ́n ń bẹ lọ́nà, ìròyìn sì dé ọ̀dọ̀ Dafidi pé, “Absalomu pa gbogbo àwọn ọmọ ọba, ọ̀kan kò sì kù nínú wọn.”
30 E sucedeu, enquanto eles estavam no caminho, que chegaram novas a Davi, dizendo: Absalão matou todos os filhos do rei, e nenhum deles restou.
31 Ọba sì dìde, ó sì fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì dùbúlẹ̀ ni ilẹ̀; gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ tí wọ́n dúró tì í sì fà aṣọ wọn ya.
31 Então, o rei se levantou, e rasgou as suas vestes, e deitou-se sobre a terra; e todos os seus servos permaneceram junto com suas vestes rasgadas.
32 Jonadabu ọmọ Ṣimea arákùnrin Dafidi sì dáhùn ó sì wí pé, “Kí olúwa mi ọba má ṣe rò pé wọ́n ti pa gbogbo àwọn ọ̀dọ́mọdékùnrin àwọn ọmọ ọba; nítorí pé Amnoni nìkan ṣoṣo ni ó kú, nítorí láti ẹnu Absalomu wá ni a ti pinnu rẹ̀ láti ọjọ́ tí ó ti fi agbára mú Tamari àbúrò rẹ̀.
32 E Jonadabe, o filho de Simeia, irmão de Davi, respondeu e disse: Não suponha o meu senhor que mataram todos os moços filhos do rei; porque somente Amnom está morto; porquanto, por convocação de Absalão, foi isto determinado desde o dia em que ele forçou sua irmã Tamar.
33 Ǹjẹ́ kí olúwa mi ọba má ṣe fi nǹkan yìí sí ọkàn pé gbogbo àwọn ọmọ ọba ni o kú, nítorí Amnoni nìkan ṣoṣo ni ó kú.”
33 Agora, portanto, não leve, o meu senhor, esta coisa ao seu coração, o pensar que todos os filhos do rei estão mortos; porque somente Amnom está morto.
34 Absalomu sì sá.
34 Mas Absalão fugiu. E o moço que mantinha a guarda levantou os seus olhos, e viu, e eis que vinham muitas pessoas pelo caminho da encosta à sua retaguarda.
35 Jonadabu sì wí fún ọba pé, “Wò ó, àwọn ọmọ ọba ń bọ́; gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ó rí.”
35 E Jonadabe disse ao rei: Eis que vêm os filhos do rei; como disse o teu servo, assim o é.
36 Nígbà tí ó sì parí ọ̀rọ̀ tí ó ń sọ, sì wò ó àwọn ọmọ ọba dé, wọ́n sì gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sì sọkún, ọba àti gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú sì sọkún ńlá ńlá.
36 E sucedeu, tão logo ele terminou de falar, que chegaram os filhos do rei, e ergueram a sua voz e choraram; e também o rei e todos os seus servos choraram mui amargamente.
37 Absalomu sì sá, ó sì tọ Talmai lọ, ọmọ Ammihudu, ọba Geṣuri. Dafidi sì ń káàánú nítorí ọmọ rẹ̀ lójoojúmọ́.
37 Então Absalão fugiu, e foi até Talmai, filho de Amiúde, rei de Gesur. E Davi se lamentava pelo seu filho todos os dias.
38 Absalomu sì sá, ó sì lọ sí Geṣuri ó sì gbé ibẹ̀ lọ́dún mẹ́ta.
38 Então Absalão fugiu, e foi até Gesur, e ali permaneceu três anos.
39 Ọkàn Dafidi ọba sì fà gidigidi sí Absalomu, nítorí tí ó tí gba ìpẹ̀ ní ti Amnoni: ó sá à ti kú.
39 E a alma do rei Davi ansiava em ir até Absalão; porque ele estava consolado acerca de Amnom, sabendo que ele estava morto.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Samuel 13, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.