2 Reis 9

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Wòlíì Eliṣa fi àṣẹ pe ọkùnrin kan láti ẹgbẹ́ àwọn wòlíì, ó sì wí fún un pé, “Ki agbádá rẹ sínú ọ̀já àmùrè rẹ, gba ṣágo kékeré òróró yìí pẹ̀lú rẹ, kí o sì lọ sí Ramoti Gileadi.
1 E Eliseu, o profeta, chamou um dos filhos dos profetas, e disse-lhe: Cinge os teus lombos, e toma esta caixa de azeite na tua mão, e vai até Ramote-Gileade;
2 Nígbà tí o bá dé bẹ̀, wá Jehu ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi kiri. Lọ sí ọ̀dọ̀ ọ rẹ̀, mú un kúrò lọ́dọ̀ àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀, kí o sì mú un wọ inú yàrá lọ́hùn ún lọ.
2 e quando tu fores para lá, procura Jeú, o filho de Josafá, o filho de Ninsi, e entra, e faz com que ele se levante dentre os seus irmãos, e leva-o para uma câmara interior;
3 Nígbà náà, mú ṣágo kékeré yìí, kí o sì da òróró náà lé e lórí, kí o sì wí pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Èmi fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli.” ’ Nígbà náà, ṣí ìlẹ̀kùn, kí o sì sáré, má ṣe jáfara!”
3 então, toma a caixa de azeite, e a derrama sobre a sua cabeça, e diz: Assim diz o SENHOR: Tenho te ungido rei sobre Israel. Então, abre a porta, e foge, e não te detenhas.
4 Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀dọ́mọkùnrin náà, wòlíì náà lọ sí Ramoti Gileadi.
4 Assim, o jovem profeta foi até Ramote-Gileade.
5 Nígbà tí ó dé, ó rí àwọn olórí ẹgbẹ́ ọmọ-ogun tí wọ́n jókòó papọ̀. “Èmi ní iṣẹ́ fún ọ, olórí,” Ó wí.
5 E, quando ele chegou, eis que os capitães do exército estavam assentados; e ele disse: Eu tenho um recado para ti, ó capitão. E Jeú disse: Para qual dentre todos nós? E ele disse: Para ti, ó capitão.
6 Jehu dìde sókè, ó sì wọ inú ilé lọ. Nígbà náà, wòlíì náà da òróró náà sórí Jehu; ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Èmi fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí àwọn ènìyàn Olúwa Israẹli.
6 E ele se levantou, e entrou na casa; e derramou o azeite sobre a sua cabeça, e lhe disse: Assim diz o SENHOR Deus de Israel: Tenho te ungido rei sobre o povo do SENHOR, a saber, sobre Israel.
7 Kí ìwọ kí ó pa ilé Ahabu ọ̀gá à rẹ̀ run, Èmi yóò sì gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ gbogbo àwọn ìránṣẹ́ mi wòlíì àti gbogbo ẹ̀jẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ Olúwa tí a ta sílẹ̀ látọwọ́ ọ Jesebeli.
7 E tu ferirás a casa de Acabe, o teu mestre, para que eu possa vingar o sangue dos meus servos, os profetas, e o sangue de todos os servos do SENHOR, da mão de Jezabel.
8 Gbogbo ilé Ahabu yóò ṣègbé. Èmi yóò gé e kúrò láti orí Ahabu gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin tí ó gbẹ̀yìn ni Israẹli, ẹrú tàbí òmìnira.
8 Porque toda a casa de Acabe perecerá; e eu cortarei de Acabe aquele que mija contra a parede, e aquele que está escravo e livre em Israel;
9 Èmi yóò ṣe ilé Ahabu gẹ́gẹ́ bí ilé Jeroboamu ọmọ Nebati àti ilé Baaṣa ọmọ Ahijah.
9 e eu farei a casa de Acabe como a casa de Jeroboão, o filho de Nebate, e como a casa de Baasa, o filho de Aías;
10 Fún Jesebeli, ajá ni yóò jẹ ẹ́ ní oko Jesreeli, kò sì sí ẹni tí yóò sin òkú rẹ̀.’ ” Nígbà náà ó ṣí ìlẹ̀kùn, ó sì sálọ.
10 e os cães comerão Jezabel na porção de Jezreel, e não haverá ali nenhum para enterrá-la. E ele abriu a porta, e fugiu.
11 Nígbà tí Jehu jáde lọ bá àwọn ọgbà ìjòyè e rẹ̀, ọ̀kan nínú wọn sì bi í pé, “Ṣé gbogbo nǹkan dára?”
11 Então, Jeú saiu até aos servos do seu senhor; e um lhe disse: Está tudo bem? Por que este louco veio até ti? E ele disse-lhes: Vós conheceis o homem e a sua comunicação.
12 “Ìyẹn kì í ṣe òótọ́!” Wọ́n wí. “Sọ fún wa.”
12 E eles disseram: Isto é falso; conta-nos agora. E disse-lhe: Assim e assim falou ele a mim, dizendo: Assim diz o SENHOR: Tenho te ungido rei sobre Israel.
13 Wọ́n ṣe gírí, wọ́n sì mú agbádá a wọn, wọ́n sì tàn wọ́n sí abẹ́ rẹ̀ ní orí àtẹ̀gùn. Nígbà náà, wọ́n fọn ìpè, wọ́n sì kígbe, “Jehu jẹ ọba!”
13 Então eles apressaram-se, e tomando cada um a sua vestimenta puseram debaixo dele, no alto das escadarias, e sopraram as trombetas, dizendo: Jeú é rei.
14 Bẹ́ẹ̀ ni Jehu ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi, dìtẹ̀ sí Joramu. (Nísinsin yìí Joramu àti gbogbo Israẹli ti ń dáàbò bo Ramoti Gileadi nítorí Hasaeli ọba Aramu.
14 Assim, Jeú, o filho de Josafá, o filho de Ninsi, conspirou contra Jorão. (Ora, Jorão havia aprisionado Ramote-Gileade, ele e todo o Israel, por causa de Hazael, rei da Síria.
15 ṣùgbọ́n ọba Joramu ti padà sí Jesreeli láti lọ sàn nínú ọgbẹ́ tí àwọn ará Aramu ti dá sí i lára nínú ogun pẹ̀lú ọba Hasaeli ti Aramu.) Jehu wí pé, “Tí èyí bá jẹ́ ọ̀nà tí ò ń rò, má ṣe jẹ́ kí ẹnìkankan kí ó yọ jáde nínú ìlú ńlá láti lọ sọ ìròyìn náà ní Jesreeli.”
15 Porém o rei Jorão havia retornado a Jezreel para ser curado dos ferimentos que os sírios lhe haviam causado, quando ele lutou contra Hazael, rei da Síria). E Jeú disse: Se isto está em vossas mentes, então que ninguém saia nem escape da cidade para ir e contar isto em Jezreel.
16 Nígbà náà Jehu wọ inú kẹ̀kẹ́ rẹ̀, ó sì gùn ún lọ sí Jesreeli, nítorí Joramu ń sinmi níbẹ̀ àti Ahasiah ọba Juda sì sọ̀kalẹ̀ láti wá wò Joramu.
16 Assim, Jeú subiu em uma carruagem, e foi até Jezreel; porque Jorão ali estava deitado. E Acazias, rei de Judá, havia descido para ver Jorão.
17 Nígbà tí olùṣọ́ kan tí ó dúró ní ilé ìṣọ́ ní Jesreeli, rí ọ̀wọ́ ogun Jehu tí wọ́n ń súnmọ́ tòsí, ó pè jáde, “Mo rí àwọn ọ̀wọ́ ogun tí ó ń bọ̀.”
17 E um atalaia estava ali de pé sobre a torre em Jezreel, e ele espionava a companhia de Jeú enquanto ele vinha, e disse: Vejo uma companhia. E Jorão disse: Toma um cavaleiro, e envia-o para se encontrar com eles, e que ele diga: Isto é paz?
18 Ọkùnrin ẹlẹ́ṣin náà, lọ láti lọ bá Jehu ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí ọba wí: ‘Ṣé ìwọ wá pẹ̀lú àlàáfíà?’ ”
18 Assim lá se foi um em lombo de cavalo para se encontrar com ele, e disse: Assim diz o rei: Isto é paz? E Jeú disse: O que tens tu a fazer com a paz? Volve-te para trás de mim. E o atalaia contou, dizendo: O mensageiro chegou até eles, mas ele não retorna.
19 Bẹ́ẹ̀ ni, ọba rán ọkùnrin ẹlẹ́ṣin kejì. Nígbà náà ó wá sí ọ̀dọ̀ wọn, ó wí pé, “Èyí ni ohun tí ọba sọ:
19 Então, ele enviou um segundo em lombo de cavalo, o qual veio a eles, e disse: Assim diz o rei: Isto é paz? E Jeú respondeu: O que tens tu a fazer com a paz? Volve-te para trás de mim.
20 Olùṣọ́ náà sì fi sùn. “Ó ti dé ọ̀dọ̀ wọn, ṣùgbọ́n kò tún padà wá mọ́ pẹ̀lú. Wíwá rẹ̀ sì dàbí ti Jehu ọmọ Nimṣi, ó ń wa kẹ̀kẹ́ bí ti aṣiwèrè.”
20 E o atalaia contou, dizendo: Ele chegou mesmo até eles, e não retorna; e o conduzir é semelhante ao conduzir de Jeú, o filho de Ninsi; pois conduz furiosamente.
21 “Fi ìwọ̀ kọ́ kẹ̀kẹ́ ogun mi.” Joramu pa á láṣẹ. Àti nígbà tí a fi kọ́, Joramu ọba Israẹli àti Ahasiah ọba Juda, gun kẹ̀kẹ́ lọ, olúkúlùkù nínú kẹ̀kẹ́ ogun tirẹ̀, láti lọ bá Jehu. Wọ́n bá a pàdé ní ibi oko tí ó ti jẹ́ ti Naboti ará Jesreeli.
21 E Jorão disse: Preparai-vos. E a sua carruagem foi preparada. E Jorão, rei de Israel, e Acazias, rei de Judá saíram, cada um na sua carruagem, e eles saíram contra Jeú, e o encontraram na porção de Nabote, o jezreelita.
22 Nígbà tí Joramu rí Jehu, ó béèrè pé, “Ṣé ìwọ wá pẹ̀lú àlàáfíà, Jehu?”
22 E sucedeu, quando Jorão viu Jeú, que ele disse: Isto é paz, Jeú? E ele respondeu: Que paz, enquanto as prostituições da tua mãe, Jezabel, e as suas feitiçarias são tantas?
23 Joramu yí ọwọ́ rẹ̀ padà, ó sì sálọ, ó sì ń pe Ahasiah, “Ọ̀tẹ̀ dé, Ahasiah!”
23 E Jorão virou as suas mãos, e fugiu, e disse a Acazias: É traição, ó Acazias.
24 Nígbà náà, Jehu fa ọrun rẹ̀, ó sì yin Joramu láàrín èjìká méjèèjì. Ọfà náà sì wọ inú ọkàn rẹ̀, ó sì ṣubú lulẹ̀ láti orí kẹ̀kẹ́ rẹ̀.
24 E Jeú entesou um arco com toda a sua força, e feriu Jorão entre os seus braços, e a flecha saiu no seu coração, e ele afundou-se na sua carruagem.
25 Jehu sọ fún Bidikari, balógun kẹ̀kẹ́ ẹ rẹ̀ pé, “Gbé e sókè kí ó sì jù ú sí orí oko tí ó jẹ́ ti Naboti ará Jesreeli. Rántí bí èmi àti ìwọ ti ń gun kẹ̀kẹ́ papọ̀ lẹ́yìn Ahabu baba à rẹ nígbà tí Olúwa sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀,
25 Então, disse Jeú a Bidcar, o seu capitão: Levanta-o e lança-o na porção do campo de Nabote, o jezreelita; porque te lembras como, quando eu e tu cavalgávamos juntos atrás de Acabe, o seu pai, o SENHOR colocou esta carga sobre ele;
26 ‘Ní àná, mo rí ẹ̀jẹ̀ Naboti pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ni Olúwa wí.’ Ǹjẹ́ nítorí náà, ẹ gbé e sókè, kí o sì jù ú sí orí ilẹ̀ oko náà ní ìbámu pẹ̀lú ọ̀rọ̀ Olúwa.”
26 seguramente, ontem vi o sangue de Nabote, e o sangue dos seus filhos, diz o SENHOR; e eu me desforrarei de ti neste pedaço de terra, diz o SENHOR. Agora, portanto, toma-o e lança-o no pedaço de terra, segundo a palavra do SENHOR.
27 Nígbà tí Ahasiah ọba, Juda rí ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀, ó sálọ sójú ọ̀nà sí Beti-Haggani. Jehu sì lépa rẹ̀, ó ń kígbe, “Pa á pẹ̀lú!” Wọ́n ṣá a ní ọgbẹ́ nínú kẹ̀kẹ́ ẹ rẹ̀ ní ọ̀nà lọ sí Guri lẹ́bàá a Ibleamu, ṣùgbọ́n ó sálọ sí Megido, ó sì kú síbẹ̀.
27 Porém, quando Acazias, o rei de Judá, viu isto, ele fugiu pelo caminho da casa do jardim. E Jeú o perseguiu, e disse: Feri-o também na carruagem. E eles assim o fizeram na subida de Gur, a qual fica junto a Ibleão. E ele fugiu para Megido, e lá morreu.
28 Ìránṣẹ́ rẹ̀ sì gbé e pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ lọ sí Jerusalẹmu, ó sì sin ín pẹ̀lú, baba a rẹ̀ nínú ibojì rẹ̀ ní ìlú ńlá ti Dafidi.
28 E os seus servos o carregaram em uma carruagem até Jerusalém, e o sepultaram no seu sepulcro com os seus pais, na cidade de Davi.
29 (Ní ọdún kọkànlá ti Joramu ọmọ Ahabu, Ahasiah ti di ọba Juda.)
29 E no décimo primeiro ano de Jorão, o filho de Acabe, começou a reinar Acazias sobre Judá.
30 Nígbà náà Jehu lọ sí Jesreeli. Nígbà tí Jesebeli gbọ́ nípa rẹ̀, ó kun ojú u rẹ̀, ó to irun rẹ̀, ó sì wò jáde láti ojú fèrèsé.
30 E quando Jeú chegou a Jezreel, Jezabel ouviu a respeito; e ela pintou a face, e ataviou a cabeça, e olhou por uma janela.
31 Bí Jehu ti wọ ẹnu ìlẹ̀kùn, ó béèrè, “Ṣé ìwọ wá ní àlàáfíà, Simri, ìwọ olùpa ọ̀gá à rẹ?”
31 E quando Jeú entrou pelo portão, ela disse: Teve paz Zinri, que matou a seu senhor?
32 Ó gbójú sókè láti wo fèrèsé, ó sì pè jáde, “Ta ni ó wà ní ẹ̀gbẹ́ mi? Ta ni?” Ìwẹ̀fà méjì tàbí mẹ́ta bojú wò ó nílẹ̀.
32 E ele levantou a sua face em direção à janela, e disse: Quem está do meu lado? Quem? E ali olhavam para ele dois ou três eunucos.
33 Jehu sọ wí pé, “Gbé e jù sílẹ̀!” Wọ́n sì jù ú sílẹ̀. Díẹ̀ nínú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sì fọ́n sí ara ògiri àti àwọn ẹṣin bí wọ́n ti tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀ wọn.
33 E ele disse: Lançai-a abaixo. Assim, eles a lançaram abaixo; e parte do seu sangue foi respingada na parede, e nos cavalos; e ele calcou-a sob os seus pés.
34 Jehu wọ inú ilé lọ, ó jẹ, ó sì mu. “Tọ́jú obìnrin yẹn tí a fi bú,” Ó wí, “Kí o sì sin ín, nítorí ọmọbìnrin ọba ni ó jẹ́.”
34 E, quando ele havia entrado, ele comeu e bebeu, e disse: Ide e vede agora esta mulher maldita, e sepultai-a; porque ela é filha de um rei.
35 Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n jáde lọ láti lọ sin ín, wọn kò rí nǹkan kan àyàfi agbárí i rẹ̀, ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèèjì àti ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì.
35 E eles foram sepultá-la; mas dela não encontraram nada além da caveira, e os pés, e as palmas das suas mãos.
36 Wọ́n padà lọ sọ fún Jehu, ẹni tí ó wí pé, “Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ nípasẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ Elijah ará Tiṣibi wí pé, ‘Ní orí oko Jesreeli ni àwọn ajá yóò ti jẹ ẹran-ara Jesebeli.
36 Pelo que eles retornaram, e contaram-lhe. E ele disse: Esta é a palavra do SENHOR, a qual ele falou pelo seu servo Elias, o tisbita, dizendo: Na porção de Jezreel os cães comerão a carne de Jezabel;
37 Òkú Jesebeli yóò dàbí ohun ẹ̀gbin ní orí oko Jesreeli, dé bi pé, ẹnikẹ́ni kì yóò lè sọ pé, “Jesebeli ni èyí.” ’ ”
37 e a carcaça de Jezabel será como esterco sobre a face do campo na porção de Jezreel; de modo que não dirão: Esta é Jezabel.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Reis 9, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.