2 Reis 1

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Lẹ́yìn ikú Ahabu, Moabu ṣọ̀tẹ̀ sí Israẹli.
1 Então, Moabe se rebelou contra Israel depois da morte de Acabe.
2 Nísinsin yìí Ahasiah ti ṣubú láàrín fèrèsé láti òkè yàrá rẹ̀ tí ó wà ní Samaria, ó sì fi ara pa. Ó sì rán oníṣẹ́, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ lọ ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni, bóyá èmi ó lè rí ìwòsàn ìfarapa yìí.”
2 E Acazias caiu através de uma grade na sua câmara superior que ficava em Samaria, e ficou enfermo; e ele enviou mensageiros, e disse-lhes: Ide, consultai Baal-Zebube, o deus de Ecrom, se eu me recuperarei desta enfermidade.
3 Ṣùgbọ́n angẹli Olúwa wí fún Elijah ará Tiṣibi pé, “Lọ sókè kí o lọ bá ìránṣẹ́ ọba Samaria kí o sì béèrè lọ́wọ́ wọn, ‘Ṣé nítorí pé kò sí Ọlọ́run ní Israẹli ni ẹ̀yìn fi jáde lọ ṣèwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu òrìṣà Ekroni?’
3 Todavia, o anjo do SENHOR disse a Elias, o tisbita: Levanta-te e sobe para se encontrar com os mensageiros do rei de Samaria, e diz a eles: Porventura, não há um Deus em Israel, para irdes consultar Baal-Zebube, o deus de Ecrom?
4 Nítorí náà ohun tí Olúwa sọ ní èyí, ‘Ìwọ kò ní kúrò lórí ibùsùn tí o dùbúlẹ̀ lé. Dájúdájú ìwọ yóò kú!’ ” Bẹ́ẹ̀ ni Elijah lọ.
4 Agora, portanto, assim diz o SENHOR: Tu não descerás daquela cama na qual subiste, mas certamente morrerás. E Elias partiu.
5 Nígbà tí ìránṣẹ́ náà padà sí ọ̀dọ̀ ọba, ó béèrè ní ọwọ́ wọn pé, “Kí ni ó dé tí ẹ̀yin fi tètè padà wá?”
5 E, quando os mensageiros, retornaram a ele, ele lhes disse: Por que vós retornastes?
6 Wọ́n dáhùn pé, “Ọkùnrin kan wá láti pàdé wa, ó sì wí fún wa pé, ‘Ẹ padà sí ọ̀dọ̀ ọba tí ó rán an yín kí ẹ sì wí fún un pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Ṣé nítorí wí pé kò sí Ọlọ́run ní Israẹli ni o fi ń rán àwọn ènìyàn láti lọ ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni? Nítorí náà ìwọ kò ní fi orí ibùsùn tí ìwọ dùbúlẹ̀ lé sílẹ̀. Láìsí àní àní ìwọ yóò kùú!” ’ ”
6 E eles lhe disseram: Um homem subiu ali para se encontrar conosco, e nos disse: Ide, voltai novamente ao rei que vos enviou e dizei-lhe: Assim diz o SENHOR: Porventura não há um Deus em Israel que mandas consultar Baal-Zebube, o deus de Ecrom? Portanto, tu não descerás daquela cama na qual subiste, mas certamente morrerás.
7 Ọba béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Irú ọkùnrin wo ni ó wá pàdé yín, tí ó sì sọ irú èyí fún un yín?”
7 E ele lhes disse: Que tipo de homem era este que subiu para vos encontrar, e vos disse estas palavras?
8 Wọ́n dáhùn pé, “Ó jẹ́ ọkùnrin tí ó wọ ẹ̀wù onírun lára pẹ̀lú ọ̀já àmùrè aláwọ tí ó gbà yíká ìbàdí rẹ̀.”
8 E eles lhe responderam: Ele era um homem peludo, e cingido com um cinto de couro nos lombos. E ele disse: É Elias, o tisbita.
9 Ó sì rán balógun pẹ̀lú àwọn ẹgbẹ́ ogun àádọ́ta rẹ̀. Balógun náà sì gòkè tọ Elijah lọ, ẹni tí ó jókòó ní orí òkè, wọ́n sì wí fún un pé, “Ènìyàn Ọlọ́run, ọba wí pé, ‘Sọ̀kalẹ̀ wá!’ ”
9 Então, o rei enviou a ele um capitão de cinquenta com os seus cinquenta. E subiu até ele; e, eis que ele se assentava sobre o cume de um outeiro. E falou-lhe: A ti, homem de Deus, o rei disse: Desce.
10 Elijah sì dá balógun lóhùn pé, “Tí ó bá jẹ́ wí pé ènìyàn Ọlọ́run ni mí, kí iná kí ó sọ̀kalẹ̀ láti òkè ọ̀run wá kí ó sì jó ìwọ àti àwọn àádọ́ta ọkùnrin rẹ!” Nígbà náà iná náà sì sọ̀kalẹ̀ wá láti òkè ọ̀run ó sì jó balógun àti àwọn ènìyàn rẹ̀.
10 E Elias respondeu e disse ao capitão dos cinquenta: Se eu for um homem de Deus, então que desça fogo do céu, e consuma a ti e aos teus cinquenta. E desceu ali fogo do céu, e consumiu a ele e aos cinquenta.
11 Ọba sì tún rán balógun àádọ́ta pẹ̀lú àwọn ènìyàn àádọ́ta rẹ̀ sí Elijah. Balógun náà sì wí fún un pé, “Ènìyàn Ọlọ́run, èyí ni ohun tí ọba sọ, ‘Sọ̀kalẹ̀ kánkán!’ ”
11 Novamente, ele lhe enviou um outro capitão de cinquenta com os seus cinquenta. E ele lhe respondeu, dizendo: Ó homem de Deus, assim disse o rei: Desce depressa.
12 “Tí èmi bá jẹ́ ènìyàn Ọlọ́run,” Elijah sì dáhùn, “Ǹjẹ́ kí iná kí ó sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run kí ó sì jó ọ run àti àwọn àádọ́ta ènìyàn rẹ!” Nígbà náà iná Ọlọ́run sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run ó sì jó o run pẹ̀lú àwọn àádọ́ta ènìyàn rẹ̀.
12 E Elias respondeu e disse a eles: Se eu for um homem de Deus, então que desça fogo do céu, e consuma a ti e aos teus cinquenta. E o fogo de Deus desceu do céu, e consumiu a ele e aos cinquenta.
13 Bẹ́ẹ̀ ni ọba tún rán balógun kẹta pẹ̀lú àwọn àádọ́ta ọkùnrin. Balógun ẹ̀ẹ̀kẹ́ta lọ sí òkè, ó sì kúnlẹ̀ lórí orókún rẹ̀ níwájú Elijah. “Ènìyàn Ọlọ́run,” Ó sì bẹ̀bẹ̀ pé, “Ìwọ ènìyàn Ọlọ́run, jọ̀wọ́ jẹ́ kí ẹ̀mí mi àti ẹ̀mí àwọn àádọ́ta ìránṣẹ́ rẹ wọ̀nyí ṣọ̀wọ́n ní ojú rẹ!
13 E ele lhe enviou novamente um capitão dos terceiros cinquenta com os seus cinquenta. E o terceiro capitão dos cinquenta subiu, e chegou, e caiu de joelhos diante de Elias, e buscou-lhe e lhe disse: Ó homem de Deus, suplico-te, que a minha vida e a vida destes cinquenta servos teus seja preciosa na tua visão.
14 Wò ó, iná ti sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run láti jó àwọn balógun méjì àràádọ́ta àkọ́kọ́ pẹ̀lú àràádọ́ta wọn. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ní ojúrere fún ẹ̀mí mi!”
14 Eis que desceu ali fogo do céu e queimou os dois capitães anteriores de cinquenta, com os seus cinquenta; porquanto, que a minha vida seja, agora, preciosa aos teus olhos.
15 Angẹli Olúwa sọ fún Elijah pé, “Sọ̀kalẹ̀ lọ pẹ̀lú rẹ̀; má ṣe bẹ̀rù rẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni Elijah dìde ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ pẹ̀lú rẹ̀ sí ọ̀dọ̀ ọba.
15 E o anjo do SENHOR disse a Elias: Desce com ele; não o temas. E ele se levantou, e desceu com ele até o rei.
16 Ó sọ fún ọba pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí, ‘Ṣé nítorí wí pé kò sí Ọlọ́run ní Israẹli fún ọ láti pè ni ìwọ fi rán ìránṣẹ́ lọ sí ọ̀dọ̀ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni láti lọ ṣe ìwádìí?’ Nítorí pé o ṣe èyí, ìwọ kò ní dìde lórí ibùsùn tí o dùbúlẹ̀ lé láìsí àní àní ìwọ yóò kú!”
16 E ele lhe disse: Assim diz o SENHOR: Porquanto tens enviado mensageiros para consultar Baal-Zebube, o deus de Ecrom: Porventura não há um Deus em Israel para que se consulte a sua palavra? Por tal, tu não descerás daquela cama na qual subiste, mas certamente morrerás.
17 Bẹ́ẹ̀ ó sì kú, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa tí Elijah ti sọ.
17 Assim, ele morreu segundo a palavra do SENHOR, a qual Elias falou. E Jorão reinou no seu lugar, no segundo ano de Jeorão, o filho de Josafá, rei de Judá; porque ele não tinha nenhum filho.
18 Àti ní ti gbogbo àwọn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ nígbà ìjọba Ahasiah, àti ohun tí ó ṣe, ṣe a kò ha kọ wọ́n sí inú ìwé ọdọọdún ti àwọn ọba Israẹli?
18 Ora, o restante dos atos de Acazias, os quais ele fez, não estão escritos no livro das Crônicas dos reis de Israel?

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Reis 1, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.