2 Crônicas 8

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Lẹ́yìn ogún ọdún lásìkò ìgbà tí Solomoni kọ́ ilé Olúwa àti ilé òun fúnra rẹ̀.
1 E sucedeu, ao fim de vinte anos, nos quais Salomão edificou a casa do SENHOR, e a sua própria casa,
2 Solomoni tún ìlú tí Hiramu ti fi fún un kọ́, ó sì kó àwọn ọmọ Israẹli jọ níbẹ̀ kí wọn kí ó lè máa gbé nínú ibẹ̀.
2 que as cidades que Hirão havia restaurado para Salomão, Salomão as edificou, e fez com que os filhos de Israel ali habitassem.
3 Nígbà náà Solomoni lọ sí Hamati-Ṣoba ó sì borí rẹ̀.
3 E Salomão foi a Hamate-Zobá, e predominou contra ela.
4 Ó sì tún kọ́ Tadmori ní aginjù àti gbogbo ìlú ìṣúra tí ó ti kọ́ ní Hamati.
4 E ele edificou Tadmor no deserto, e todas as cidades-armazéns, as quais edificou em Hamate.
5 Ó sì tún kọ́ òkè Beti-Horoni àti ìsàlẹ̀ Beti-Horoni gẹ́gẹ́ bí ìlú olódi, pẹ̀lú ògiri àti pẹ̀lú ìlẹ̀kùn àti ọ̀pá ìdábùú.
5 Além disso ele edificou a alta Bete-Horom, e a baixa Bete-Horom, cidades fortificadas, com muros, portas e barras;
6 Àti gẹ́gẹ́ bí Baalati àti gbogbo ìlú ìṣúra tí Solomoni ní, àti gbogbo ìlú fún kẹ̀kẹ́ rẹ̀ àti fún àwọn ẹṣin rẹ̀ ohunkóhun tí ó bá yẹ ní kókó ní Jerusalẹmu, ní Lebanoni àti ní gbogbo àyíká agbègbè tí ó ń darí.
6 e Baalate, e todas as cidades-armazéns que Salomão tinha, e todas as cidades das carruagens, e as cidades dos cavaleiros, e tudo o que Salomão desejou edificar em Jerusalém, e no Líbano, e em toda a terra do seu domínio.
7 Gbogbo àwọn ènìyàn tí ó kúrò láti ara àwọn ará Hiti, ará Amori, ará Peresi, ará Hifi àti ará Jebusi àwọn ènìyàn wọ̀nyí wọn kì í ṣe àwọn ará Israẹli,
7 E quanto a todo o povo que foi deixado dos heteus, amorreus, e dos ferezeus, e dos heveus, e dos jebuseus, os quais não eram de Israel,
8 èyí ni wí pé, àwọn ọmọ wọn tí ó kù sílé ní ilẹ̀ náà, tí àwọn ọmọ Israẹli kò parun àwọn ni Solomoni bu iṣẹ́ ìrú fún títí di òní yìí.
8 dos seus filhos, que ficaram depois deles na terra, aos quais os filhos de Israel não consumiram, Salomão fez com que eles pagassem tributo até este dia.
9 Ṣùgbọ́n Solomoni kò mú ọmọ ọ̀dọ̀ lára àwọn ọmọ Israẹli, wọn jẹ́ ọ̀gágun rẹ̀, olùdarí àwọn oníkẹ̀kẹ́ àti olùdarí kẹ̀kẹ́ àti àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀.
9 Porém, dos filhos de Israel, Salomão não fez servos para a sua obra; mas eles foram homens de guerra, e chefes dos seus capitães, e capitães das suas carruagens e cavaleiros.
10 Wọ́n sì tún jẹ́ olórí aláṣẹ fún ọba Solomoni, àádọ́ta ó lé nígba (250) àwọn alákòóso lórí àwọn ènìyàn.
10 E estes foram os chefes dos oficiais do rei Salomão, a saber, duzentos e cinquenta, que governaram sobre o povo.
11 Solomoni gbé ọmọbìnrin Farao sókè láti ìlú Dafidi lọ sí ibi tí ó ti kọ́ fún un, nítorí ó wí pé, “Aya mi kò gbọdọ̀ gbé nínú ilé Dafidi ọba Israẹli nítorí ibi tí àpótí ẹ̀rí Olúwa bá tí wọ̀, ibi mímọ́ ni.”
11 E Salomão fez subir a filha de Faraó da cidade de Davi até a casa que ele havia edificado para ela; porque ele disse: A minha esposa não habitará na casa de Davi, rei de Israel, porque santos são os lugares, para os quais a arca do SENHOR veio.
12 Lórí pẹpẹ Olúwa tí ó ti kọ́ níwájú ìloro náà, Solomoni sì rú ẹbọ sísun sí Olúwa,
12 Então, Salomão ofereceu ofertas queimadas ao SENHOR sobre o altar do SENHOR, o qual ele havia edificado diante do pórtico,
13 nípa ìlànà ojoojúmọ́ fún ẹbọ rírú tí a pàṣẹ láti ọ̀dọ̀ Mose wá fún ọjọ́ ìsinmi, oṣù tuntun àti lẹ́rìn mẹ́ta lọ́dún, ní àjọ àìwúkàrà, ní àjọ ọ̀sẹ̀ méje àti àjọ àgọ́.
13 segundo uma certa proporção todos os dias, oferecendo de acordo com o mandamento de Moisés, nos shabats, e nas luas novas, e nas festas solenes, três vezes por ano, a saber, na festa dos pães ázimos, e na festa das semanas, e na festa dos tabernáculos.
14 Ní pípamọ́ pẹ̀lú ìlànà baba rẹ̀ Dafidi, ó sì yan ipa àwọn àlùfáà fún iṣẹ́ wọn àti àwọn ọmọ Lefi láti jẹ́ adarí láti máa yin àti láti máa ṣe ìránṣẹ́ àwọn àlùfáà gẹ́gẹ́ bí ìlànà ojoojúmọ́. Ó sì tún yàn àwọn olùṣọ́nà nípa pípín sí olúkúlùkù ẹnu-ọ̀nà, nítorí èyí ni Dafidi ènìyàn Ọlọ́run ti paláṣẹ.
14 E ele indicou, de acordo com a ordem do seu pai Davi, as turmas dos sacerdotes para o seu serviço, e os levitas para os seus encargos, de louvar e ministrar diante dos sacerdotes, como a obrigação de todos os dias exigia; os porteiros, também, pelas suas turmas a cada porta; porque assim o havia ordenado Davi, homem de Deus.
15 Wọn kò sì yà kúrò nínú àṣẹ ọba sí àwọn àlùfáà tàbí sí àwọn ọmọ Lefi, nínú ohunkóhun, àti pẹ̀lú ti ìṣúra.
15 E eles não se desviaram do mandado do rei aos sacerdotes e levitas acerca de nenhuma questão, nem acerca dos tesouros.
16 Gbogbo iṣẹ́ Solomoni ni a gbé jáde láti ọjọ́ ìfi ìpìlẹ̀ ilé Olúwa lélẹ̀ títí ó fi di ọjọ́ ìparí. Bẹ́ẹ̀ ni ilé Olúwa sì parí.
16 Ora, toda a obra de Salomão estava preparada desde o dia da fundação da casa do SENHOR, e até ser terminada. Assim a casa do SENHOR foi aperfeiçoada.
17 Nígbà náà ni Solomoni lọ sí Esioni-Geberi àti Elati ní Edomu létí òkun.
17 Então, foi Salomão a Eziom-Geber, e a Elate, à beira-mar na terra de Edom.
18 Hiramu sì fi ọ̀kọ̀ ránṣẹ́ sì i nípa àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀, àwọn ọkùnrin tí ó mòye Òkun. Èyí pẹ̀lú àwọn ènìyàn Solomoni, lọ sí Ofiri wọ́n sì gbé àádọ́ta lé ní irinwó (450) tálẹ́ǹtì wúrà wá, padà èyí tí wọ́n sì mú tọ ọba Solomoni wá.
18 E Hirão lhe enviou, pelas mãos dos seus servos, navios e servos que tinham conhecimento do mar; e foram com os servos de Salomão até Ofir, e tomaram de lá quatrocentos e cinquenta talentos de ouro, e os trouxeram até o rei Salomão.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Crônicas 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.