2 Crônicas 23
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Ní ọdún keje, Jehoiada fi agbára rẹ̀ hàn. O dá májẹ̀mú pẹ̀lú àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún kan, Asariah ọmọ Jerohamu, Iṣmaeli ọmọ Jehohanani Asariah ọmọ Obedi, Maaseiah ọmọ Adaiah àti Elisafati ọmọ Sikri.
1 E no sétimo ano, Joiada se fortaleceu e tomou consigo em pacto os capitães de centúrias, Azarias, o filho de Jeroão, e Ismael, o filho de Joanã, e Azarias, o filho de Obede, e Maaseias, o filho de Adaías, e Elisafate, o filho de Zicri.
2 Wọ́n lọ sí gbogbo Juda, wọ́n sì pe àwọn ará Lefi àti àwọn olórí àwọn ìdílé àwọn ará Israẹli láti gbogbo àwọn ìlú jọ. Nígbà tí wọ́n wá sí Jerusalẹmu.
2 E eles saíram por Judá e reuniram os levitas de todas as cidades de Judá, e os chefes dos pais de Israel, e vieram a Jerusalém.
3 Gbogbo ìpéjọ náà dá májẹ̀mú pẹ̀lú ọba ní ilé Ọlọ́run.
3 E toda a congregação fez um pacto com o rei na casa de Deus. E ele lhes disse: Eis que o filho do rei reinará, como o SENHOR tem dito acerca dos filhos de Davi.
4 Nísinsin yìí èyí ni ohun tí ó yẹ kí ó ṣe, ìdámẹ́ta àlùfáà yín àti àwọn ará Lefi tí ó ń lọ fún iṣẹ́ ìsìn ní ọjọ́ ìsinmi ni kí ó bojútó àwọn ìlẹ̀kùn.
4 Isto é o que haveis de fazer: uma terça parte de vós, dos sacerdotes e dos levitas que entram no shabat, será guardas das portas;
5 Ìdámẹ́ta yín níbi ààfin ọba àti ìdámẹ́ta níbi ẹnu odi ìdásílẹ̀ àti gbogbo ọkùnrin mìíràn ni kí ó wà ní àgbàlá ààfin ilé Olúwa.
5 e uma terça parte estará junto à casa do rei; e uma terça parte junto ao portão do fundamento; e todo o povo estará nos átrios da casa do SENHOR.
6 Kò sí ẹnìkan tí ó gbọdọ̀ wọ inú ilé Olúwa yàtọ̀ sí àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi tí a rán ní iṣẹ́ ìsìn. Wọ́n lè wọlé nítorí tí a ti yà wọ́n sọ́tọ̀, ṣùgbọ́n gbogbo ọkùnrin mìíràn ni kí wọn ó sọ ohun tí Olúwa ti yàn fún wọn.
6 Porém, que ninguém entre na casa do SENHOR, exceto os sacerdotes e aqueles que ministram dos levitas; eles entrarão, porque eles são santos; mas todo o povo deve guardar a vigília do SENHOR.
7 Àwọn ará Lefi gbọdọ̀ wà ní ìdúró ṣinṣin yí ọba ká. Olúkúlùkù pẹ̀lú àwọn nǹkan ìjà ní ọwọ́ rẹ̀. Ẹnikẹ́ni tí ó bá wọ ilé Olúwa ni kí ẹ pa. Ẹ dúró ti ọba níbikíbi tí ó bá lọ.”
7 E os levitas cercarão o rei em redor, cada homem com as suas armas na sua mão; e qualquer outro que entrar na casa, este será levado à morte; mas estejais com o rei quando ele entrar e quando ele sair.
8 Àwọn ará Lefi àti gbogbo ọkùnrin Juda ṣe gẹ́gẹ́ bí Jehoiada àlùfáà ti paláṣẹ. Olúkúlùkù mú àwọn ọkùnrin rẹ̀, àwọn tí wọ́n lọ fún iṣẹ́ ìsìn ní ọjọ́ ìsinmi àti àwọn tí wọ́n ń kúrò ní ibi iṣẹ́. Nítorí Jehoiada àlùfáà kò ì tí tú ìpín kankan sílẹ̀.
8 Assim, os levitas e todo o Judá fizeram segundo todas as coisas que Joiada, o sacerdote, havia ordenado, e tomaram cada qual os seus homens que deveriam entrar no shabat, com aqueles que deveriam sair no shabat, pois o sacerdote Joiada não despediu as turmas.
9 Jehoiada àlùfáà, sì fi ọ̀kọ̀ àti asà, àti àpáta wọ̀n-ọn-nì, tí ó jẹ́ ti ọba Dafidi tí wọn wà ní ilé Ọlọ́run, fún àwọn balógun ọ̀rọ̀ọ̀rún.
9 Além disso, Joiada, o sacerdote, entregou aos capitães das centúrias lanças e broquéis, e escudos, que pertenciam ao rei Davi, os quais estavam na casa de Deus.
10 Ó sì to gbogbo àwọn ènìyàn ti ọba káàkiri, olúkúlùkù pẹ̀lú ohun ìjà rẹ̀ ní ọwọ́ rẹ̀, láti apá ọ̀tún ilé náà títí dé apá òsì ilé náà, lẹ́bàá pẹpẹ àti lẹ́bàá ilé náà.
10 E ele posicionou todo o povo, cada um com as suas armas na mão, desde o lado direito do templo até o lado esquerdo do templo, do lado do altar e do templo, em redor do rei.
11 Jehoiada àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ mú ọmọkùnrin ọba jáde wá wọ́n sì gbé adé sórí rẹ̀; wọ́n mú ẹ̀dà májẹ̀mú kan fún un. Wọ́n sì kéde rẹ̀ lọ́ba. Wọ́n fi àmì òróró yàn án, wọ́n sì kígbe pé, “Kí ọba kí ó pẹ́!”
11 Então, retiraram o filho do rei, e puseram sobre ele a coroa, e deram-lhe o testemunho, e o fizeram rei. E Joiada e os seus filhos o ungiram, e disseram: Deus salve o rei.
12 Nígbà tí Ataliah gbọ́ igbe àwọn ènìyàn tí wọ́n ń sáré tí wọ́n ń kígbe ọba, ó lọ sí ọ̀dọ̀ wọn ní ilé Olúwa.
12 Ora, quando Atalia ouviu o barulho do povo correndo e louvando o rei, veio ter com o povo na casa do SENHOR;
13 Ó sì wò, sì kíyèsi, ọba dúró ní ibùdó rẹ̀ ní ẹ̀bá ẹnu-ọ̀nà, àti àwọn balógun àti àwọn afùnpè lọ́dọ̀ ọba, gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà sì yọ̀, wọ́n sì fọn ìpè, àti àwọn akọrin pẹ̀lú ohun èlò ìyìn. Nígbà náà ni Ataliah fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì kégbe wí pé, “Ọ̀tẹ̀! Ọ̀tẹ̀!”
13 e ela olhou, e eis que o rei estava junto ao seu pilar, à entrada, e os príncipes e as trombetas junto ao rei; e todo o povo da terra se alegrou, e tocava trombetas, também os cantores com instrumentos de música, e assim também ensinavam a cantar louvor. Então, Atalia rasgou as suas vestes, e disse: Traição, traição.
14 Jehoiada àlùfáà mú àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún, tí ó wà ní àbojútó àwọn ọ̀wọ́ ogun, ó sì wá wí fún wọn pé, “Mú un jáde wá láàrín àwọn ọgbà, kí a sì fi idà pa ẹnikẹ́ni tí ó bá tẹ̀lé.” Nítorí tí àlùfáà ti wí pé, “Má ṣe pa á nínú ilé Olúwa.”
14 Então Joiada, o sacerdote, trouxe para fora os capitães de centúrias que foram colocados sobre o exército, e disse-lhes: Ponham-na para fora das fileiras; e quem quer que a siga, seja morto com a espada. Porque o sacerdote disse: Não a matem na casa do SENHOR.
15 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n fi ipá mú un kí ó tó dé ẹnu-ọ̀nà àbáwọlé ẹṣin ti ilé ọba, wọ́n sì ti pa á níbẹ̀.
15 Assim, eles lançaram suas mãos sobre ela; quando ela chegou na entrada do Portão dos Cavalos, junto à casa do rei, eles ali a mataram.
16 Nígbà náà ni Jehoiada, dá májẹ̀mú pé òun àti àwọn ènìyàn àti ọba yóò jẹ́ ènìyàn Olúwa.
16 E Joiada fez um pacto entre si, e entre todo o povo, e entre o rei, de que eles deveriam ser o povo do SENHOR.
17 Gbogbo àwọn ènìyàn lọ sí ilé Baali, wọ́n sì fà á ya lulẹ̀. Wọ́n fọ́ àwọn pẹpẹ àti àwọn òrìṣà, wọ́n sì pa Mattani àlùfáà Baali níwájú àwọn pẹpẹ.
17 Então, todo o povo foi até a casa de Baal e a puseram abaixo, e quebraram os seus altares e as suas imagens em pedaços, e mataram Matã, o sacerdote de Baal, diante dos altares.
18 Nígbà náà, Jehoiada tẹ àwòrán ilé Olúwa sí ọwọ́ àwọn àlùfáà tí wọ́n jẹ́ ará Lefi ẹni tí Dafidi ti fi ṣe iṣẹ́ ní ilé Olúwa láti tẹ ẹbọ sísun ti Olúwa bí a ti kọ ọ́ nínú òfin Mose, pẹ̀lú ayọ̀ àti orin kíkọ, gẹ́gẹ́ bí Dafidi ti pàṣẹ.
18 Joiada também indicou os ofícios da casa do SENHOR por mão dos sacerdotes levitas, os quais Davi havia distribuído na casa do SENHOR, para oferecerem as ofertas queimadas do SENHOR, como está escrito na lei de Moisés, com júbilo e com cânticos, como foi ordenado por Davi.
19 Ó mú àwọn olùṣọ́nà wà ni ipò ìdúró ní ẹnu odi ilé Olúwa kí ẹni aláìmọ́ nínú ohunkóhun kó má ba à wọlé.
19 E ele pôs os porteiros junto aos portões da casa do SENHOR, para que não entrasse nela ninguém imundo em coisa alguma.
20 Ó mú pẹ̀lú rẹ̀ àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún, àwọn ẹni ọlá, àwọn olórí àwọn ènìyàn àti gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà. Ó sì mú ọba sọ̀kalẹ̀ wá láti ilé Olúwa. Wọ́n lọ sínú ààfin láti ẹnu òde ti òkè. Wọ́n sì fi ọba jókòó lórí ìtẹ́.
20 E ele tomou os capitães de centúrias, e os nobres, e os governadores do povo, e todo o povo da terra e fez descer o rei da casa do SENHOR; e eles adentraram a casa do rei por intermédio do portão alto, e puseram o rei sobre o trono do reino.
21 Gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà sì yọ̀, ìlú náà sì dákẹ́ rọ́rọ́. Nítorí a pa Ataliah pẹ̀lú idà.
21 E todo o povo da terra se alegrou; e a cidade ficou calma; depois deles terem matado Atalia com a espada.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Crônicas 23, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.