2 Crônicas 17
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Jehoṣafati ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀ ó sì mú ara rẹ̀ lágbára sí lórí Israẹli.
1 E Josafá, o seu filho, reinou em seu lugar, e fortaleceu-se contra Israel.
2 Ó sì fi ogun sínú gbogbo ìlú olódi Juda ó sì kó ẹgbẹ́ ológun ní Juda àti nínú ìlú Efraimu tí Asa baba rẹ̀ ti gbà.
2 E ele posicionou forças em todas as cidades fortificadas de Judá, e pôs guarnições na terra de Judá, e nas cidades de Efraim, que Asa, o seu pai, havia tomado.
3 Olúwa sì wà pẹ̀lú Jehoṣafati nítorí, ní ọdún àkọ́kọ́ rẹ̀, ó rìn ní ọ̀nà ti baba rẹ̀ Dafidi ti rìn, kò sì fi ọ̀ràn lọ Baali.
3 E o SENHOR esteve com Josafá, porque ele andou nos primeiros caminhos do seu pai Davi, e não buscou aos baalins;
4 Ṣùgbọ́n ó wá Ọlọ́run baba rẹ̀ kiri ó sì tẹ̀lé àṣẹ rẹ̀ ju iṣẹ́ Israẹli.
4 mas buscou o SENHOR Deus do seu pai, e andou nos seus mandamentos, e não segundo as obras de Israel.
5 Olúwa sì fi ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ lábẹ́ àkóso rẹ̀, gbogbo Juda sì mú ẹ̀bùn wá fún Jehoṣafati, bẹ́ẹ̀ ni ó sì ní ọrọ̀ àti ọlá lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
5 Por isso, o SENHOR estabeleceu o reino de Israel na sua mão; e todo o Judá trazia a Josafá presentes; e ele tinha honra e riquezas em abundância.
6 Ọkàn rẹ̀ sì gbé sókè si ọ̀nà Olúwa, pẹ̀lúpẹ̀lú, ó sì mú ibi gíga wọn àti ère òrìṣà Aṣerah kúrò ní Juda.
6 E o seu coração estava exaltado nos caminhos do SENHOR; ainda mais ele removeu os lugares altos e os bosques de Judá.
7 Ní ọdún kẹta ìjọba rẹ̀, ó rán àwọn ìjòyè rẹ̀ Bene-Haili, Obadiah, Sekariah, Netaneli, Mikaiah láti máa kọ́ ni nínú ìlú Juda.
7 Além disso, no terceiro ano do seu reinado ele enviou os seus príncipes, a saber: a Ben-Hail, e a Obadias, e a Zacarias, e a Natanael, e a Micaías; para ensinarem nas cidades de Judá.
8 Wọ́n sì ní díẹ̀ lára àwọn ọmọ Lefi, àní Ṣemaiah, Netaniah, Sebadiah, Asaheli, Ṣemiramotu, Jehonatani, Adonijah, Tobijah àti Tobu-Adonijah àti àwọn àlùfáà Eliṣama àti Jehoramu.
8 E com eles, enviou os levitas, a saber: Semaías, e Netanias, e Zebadias, e Asael, e Semiramote, e Jônatas, e Adonias, e Tobias, e Tobe-Adonias, e com estes levitas os sacerdotes, Elisama e Jeroão.
9 Wọ́n ń kọ́ ni ní agbègbè Juda, wọ́n mú ìwé òfin Olúwa wọ́n sì rìn yíká gbogbo àwọn ìlú Juda wọ́n sì ń kọ́ àwọn ènìyàn.
9 E eles ensinaram em Judá, e tinham o livro da lei do SENHOR consigo, e iam por todas as cidades de Judá, e ensinavam ao povo.
10 Ìbẹ̀rù Olúwa bà lórí gbogbo ìjọba ilẹ̀ tí ó yí Juda ká, dé bi pé wọn kò bá Jehoṣafati jagun.
10 E o temor do SENHOR veio sobre todos os reinos das terras que estavam ao redor de Judá, de modo que eles não fizeram guerra contra Josafá.
11 Lára àwọn ará Filistini, mú ẹ̀bùn fàdákà gẹ́gẹ́ bí owó ọba wá fún Jehoṣafati, àwọn ará Arabia sì mú ọ̀wọ́ ẹran wá fún un, ẹgbàarindín ní ọ̀ọ́dúnrún (7,700) àgbò àti ẹgbàarindín ní ọ̀ọ́dúnrún (7,700) òbúkọ.
11 Alguns dos filisteus também traziam presentes a Josafá, e prata como tributo; e os árabes traziam-lhe rebanhos, sete mil e setecentos carneiros, e sete mil e setecentos bodes.
12 Jehoṣafati sì ń di alágbára nínú agbára sí i, ó sì kọ́ ilé olódi àti ilé ìṣúra púpọ̀ ní Juda
12 E Josafá tornou-se muitíssimo grande; e edificou fortalezas e cidades de provisões em Judá.
13 Ó sì ní ìṣúra ní ìlú Juda. Ó sì tún ní àwọn alágbára jagunjagun akọni ọkùnrin ní Jerusalẹmu.
13 E ele tinha muitos negócios nas cidades de Judá; e os homens de guerra, homens fortes e valentes, estavam em Jerusalém.
14 Iye wọn gẹ́gẹ́ bí ilé baba wọn nìwọ̀nyí.
14 E estes são os números deles de acordo com a casa dos seus pais: de Judá, os capitães de milhares; Adna, o chefe, e com ele trezentos mil homens fortes e valentes.
15 Èkejì, Jehohanani olórí, pẹ̀lú ọ̀kẹ́ mẹ́rìnlá (280,000) ọkùnrin;
15 E ao seu lado estava capitão Joanã, e com ele duzentos e oitenta mil.
16 àtẹ̀lé Amasiah ọmọ Sikri, ẹni tí ó fi ara rẹ̀ fún iṣẹ́ Olúwa pẹ̀lú ọ̀kẹ́ mẹ́wàá (200,000).
16 E junto a ele estava Amasias, o filho de Zicri, que voluntariamente se ofereceu ao SENHOR; e com ele duzentos mil homens fortes e valentes.
17 Láti ọ̀dọ̀ Benjamini:
17 E de Benjamim; Eliada, um homem forte e valente, e com ele duzentos mil homens armados com arco e escudo.
18 àtẹ̀lé Jehosabadi, pẹ̀lú ọ̀kẹ́ mẹ́sàn-án (180,000) jagunjagun ọkùnrin múra sílẹ̀ fún ogun.
18 E ao seu lado estava Jozabade, e com ele cento e oitenta mil prontamente preparados para a guerra.
19 Wọ̀nyí ni àwọn ọkùnrin tí ń dúró níwájú ọba, ní àyíká àwọn ẹni tí ó fi sínú ìlú olódi ní àyíká gbogbo Juda.
19 Estes estavam no serviço do rei; afora os que o rei tinha posto nas cidades fortificadas por todo o Judá.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Crônicas 17, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.