2 Crônicas 11
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Nígbà tí Rehoboamu dé Jerusalẹmu, ó kó ilé Juda àti Benjamini jọ, ọ̀kẹ́ mẹ́sàn-án (180,000) ènìyàn tí a yàn, tí wọ́n jẹ́ ológun, láti bá Israẹli jà kí ó lè mú ìjọba náà padà bọ̀ sọ́dọ̀ rẹ̀.
1 E quando Roboão chegou a Jerusalém, ele reuniu da casa de Judá e de Benjamim, cento e oitenta mil homens escolhidos, os quais eram guerreiros, para lutar contra Israel, para que pudesse trazer o reino de volta para Roboão.
2 Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Ṣemaiah ènìyàn Ọlọ́run wá wí pé,
2 Porém, a palavra do SENHOR veio a Semaías, o homem de Deus, dizendo:
3 “Wí fún Rehoboamu ọmọ Solomoni ọba Juda, sí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ní Juda àti Benjamini,
3 Fala a Roboão, o filho de Salomão, rei de Judá, e a todo o Israel em Judá e Benjamim, dizendo:
4 ‘Èyí ní ohun tí Olúwa wí. Ẹ má ṣe gòkè lọ láti lọ jà pẹ̀lú arákùnrin yín, ẹ lọ sílé, gbogbo yín, nítorí ti ìṣe mi nìyí.’ ” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n tẹ̀lé ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, wọ́n sì padà sẹ́yìn láti yan lọ dojúkọ Jeroboamu.
4 Assim diz o SENHOR: Não subireis, nem lutareis contra os vossos irmãos; retornai cada homem à sua casa; porque isto provém de mim. E eles obedeceram as palavras do SENHOR, e desistiram de ir contra Jeroboão.
5 Rehoboamu ń gbe ní Jerusalẹmu ó sì kọ́ àwọn ìlú fún olódi ní Juda.
5 E Roboão habitou em Jerusalém, e edificou em Judá cidades para defesa.
6 Bẹtilẹhẹmu, Etamu, Tekoa,
6 Ele edificou a Belém, e a Etã, e a Tecoa,
7 Beti-Suri, Soko, Adullamu,
7 e a Bete-Zur, e a Socó, e a Adulão,
8 Gati, Meraṣa Sifi,
8 e a Gate, e a Maressa, e a Zife,
9 Adoraimu, Lakiṣi, Aseka
9 e a Adoraim, e a Laquis, e a Azeca,
10 Sora, Aijaloni, àti Hebroni. Wọ̀nyí ni àwọn ìlú ìdáàbòbò ní Juda àti Benjamini.
10 e a Zorá, e a Aijalom, e a Hebrom, as quais estão em Judá e em Benjamim, cidades fortificadas.
11 Ó sì mú àwọn ìlú olódi lágbára, ó sì fi àwọn balógun sínú wọn àti àkójọ oúnjẹ, àti òróró àti ọtí wáìnì.
11 E fortificou as fortalezas, e pôs nelas capitães, e armazéns de provisões, e de azeite e vinho.
12 Àti ní olúkúlùkù ìlú ni ó fi asà àti ọ̀kọ̀ sí, ó sì mú wọn lágbára gidigidi, ó sì ní Juda àti Benjamini lábẹ́ rẹ̀.
12 E, em cada uma destas cidades, ele pôs escudos e lanças, e as fez sobejamente fortes, tendo Judá e Benjamim ao seu lado.
13 Àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi, láti gbogbo ẹ̀yà wọn jákèjádò Israẹli wà ní ẹ̀bá rẹ̀.
13 E os sacerdotes e os levitas que estavam em todo o Israel recorriam a ele de todos os seus termos.
14 Àwọn ará Lefi fi ìgbèríko sílẹ̀, wọ́n sì wá sí Juda àti Jerusalẹmu nítorí Jeroboamu àti àwọn ọmọ rẹ̀, ti kọ̀ wọ́n sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí àwọn àlùfáà Olúwa.
14 Porque os levitas deixaram os seus arredores e as suas possessões, e vieram para Judá e Jerusalém; porque Jeroboão e os seus filhos os expulsaram da execução do ofício sacerdotal ao SENHOR;
15 Ó sì yan àwọn àlùfáà tirẹ̀ fún àwọn ibi gíga wọ̀n-ọn-nì, àti fún àwọn ère òbúkọ, àti fún ẹgbọrọ màlúù tí ó ṣe.
15 e ele ordenou para si sacerdotes, para os lugares alto, para os demônios, e para os bezerros que ele havia feito.
16 Àwọn tó wá láti gbogbo ẹ̀yà Israẹli tí wọ́n fi ọkàn wọn fún wíwá Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tẹ̀lé àwọn ará Lefi lọ sí Jerusalẹmu láti lọ rú ẹbọ sí Olúwa Ọlọ́run baba a wọn.
16 E depois desses, de todas as tribos de Israel, tais que dispunham o seu coração a buscar o SENHOR Deus de Israel, vieram a Jerusalém, para sacrificar ao SENHOR Deus dos seus pais.
17 Ó fún ìjọba Juda ní agbára, ó sì ti Rehoboamu ọmọ Solomoni lẹ́yìn fún ọdún mẹ́ta nítorí ọdún mẹ́ta ni wọ́n fi rìn ní ọ̀nà ti Dafidi àti Solomoni ní àkókò yí.
17 Então eles fortaleceram o reino de Judá, e fortaleceram Roboão, filho de Salomão, por três anos; durante três anos eles caminharam no caminho de Davi e Salomão.
18 Rehoboamu fẹ́ Mahalati tí ó jẹ́ ọmọbìnrin ti ọmọkùnrin Dafidi Jerimoti bi àti ti Abihaili, ọmọbìnrin ti ọmọkùnrin Jese Eliabu bí.
18 E Roboão tomou para si, como esposa Maalate, a filha de Jerimote, o filho de Davi, e Abiail, a filha de Eliabe, o filho de Jessé;
19 Ó bí àwọn ọmọ fún un: Jeuṣi, Ṣemariah àti Sahamu.
19 a qual lhe deu à luz filhos: Jeús, e Semarias, e Zaão.
20 Nígbà náà, ó fẹ́ Maaka ọmọbìnrin Absalomu, tí ó bí Abijah fún Attai, Sisa àti Ṣelomiti.
20 E depois dela ele tomou Maaca, a filha de Absalão; a que lhe deu à luz: Abias, e Atai, e Ziza, e Selomite.
21 Rehoboamu fẹ́ràn Maaka ọmọbìnrin Absalomu ju èyíkéyìí nínú àwọn ìyàwó rẹ̀ àti àwọn àlè rẹ̀ lọ. Ní gbogbo rẹ̀, ó ní ìyàwó méjìdínlógún àti ọgọ́ta àlè ọmọkùnrin méjìdínlọ́gbọ̀n àti ọgọ́ta ọmọbìnrin.
21 E Roboão amou Maaca, a filha de Absalão, mais do que todas as suas esposas e do que as suas concubinas, (porquanto ele tomou dezoito esposas, e sessenta concubinas; e gerou vinte oito filhos, e sessenta filhas).
22 Rehoboamu yan Abijah ọmọ Maaka láti jẹ́ olóyè ọmọ-aládé láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀, kí ó ba à lè ṣe é ní ọba.
22 E Roboão fez com que Abias, o filho de Maaca, o chefe, fosse soberano entre os seus irmãos; porque ele queria fazê-lo rei.
23 Ó hùwà ọlọ́gbọ́n, nípa fí fọ́n díẹ̀ nínú àwọn ọmọ rẹ̀ jákèjádò ká àwọn agbègbè Juda àti Benjamini àti sí gbogbo àwọn ìlú ńlá olódi. Ó fún wọn ní ọ̀pọ̀ ohun tí wọ́n fẹ́, ó sì fẹ́ ọ̀pọ̀ ìyàwó fún wọn.
23 E ele agiu sabiamente, e dispersou a todos os seus filhos por todas as regiões de Judá e Benjamim, e toda cidade fortificada; e deu a eles provisões em fartura. E lhes desejou muitas esposas.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Crônicas 11, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.