2 Crônicas 10

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Rehoboamu sì lọ sí Ṣekemu nítorí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ti lọ síbẹ̀ láti fi jẹ ọba.
1 E Roboão foi até Siquém; pois todo Israel veio para fazê-lo rei.
2 Nígbà tí Jeroboamu ọmọ Nebati gbọ́ ẹni ti ó wà ní Ejibiti, níbi tí ó ti sá kúrò lọ́dọ̀ ọba Solomoni ó sì padà láti Ejibiti.
2 E Jeroboão, filho de Nebate, que estava então no Egito para onde fugira da presença do rei Salomão, ouvindo isto, voltou do Egito.
3 Bẹ́ẹ̀ ni nígbà náà ó sì ránṣẹ́ sí Jeroboamu àti òun àti gbogbo àwọn Israẹli lọ sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu wọ́n sì wí fún pé,
3 E eles mandaram chamá-lo. Assim Jeroboão e todo o Israel vieram falar com Roboão, dizendo:
4 “Baba rẹ gbé àjàgà tí ó wúwo lórí wa, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ mú un fúyẹ́, iṣẹ́ líle àti àjàgà wúwo tí ó gbé ka orí wa, àwa yóò sì sìn ọ́.”
4 O teu pai fez o nosso jugo doloroso; agora, portanto, alivia tu, de alguma forma, a dolorosa servidão do teu pai, e o jugo pesado que ele pôs sobre nós, e serviremos a ti.
5 Rehoboamu sì dáhùn pé, “Ẹ padà wá sọ́dọ̀ mi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta.” Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn náà sì lọ.
5 E ele lhes disse: Voltai a mim depois de três dias. E o povo partiu.
6 Nígbà náà ni ọba Rehoboamu fi ọ̀ràn lọ̀ àwọn àgbàgbà tí ó ti ń sin baba rẹ̀ Solomoni nígbà ayé rẹ̀, ó sì bi wọ́n léèrè pe, “Báwo ni ẹ̀yin yóò ṣe gbà mí ní ìmọ̀ràn láti dá àwọn ènìyàn wọ̀nyí lóhùn?”
6 E o rei Roboão tomou conselho com os anciãos que haviam se colocado de pé diante de Salomão, o seu pai, enquanto ele ainda vivia, dizendo: Que conselhos vós me dais para voltar a responder a esse povo?
7 Wọ́n sì dáhùn, “Tí ìwọ yóò bá ṣe rere sí àwọn ènìyàn wọ̀nyí kí o sì ṣe ìre fún wọn, kí o sì fún wọn ní ìdáhùn rere, wọn yóò sì máa jẹ́ ìránṣẹ́ rẹ nígbà gbogbo.”
7 E eles lhe falaram, dizendo: Se fores bondoso para com este povo, e agradá-los, e falares boas palavras, eles serão teus servos para sempre.
8 Ṣùgbọ́n Rehoboamu kọ ìmọ̀ràn náà tí àwọn àgbàgbà fi fún un, ó sì fi ọ̀rọ̀ lọ àwọn ọmọ ọkùnrin tí ó ti dàgbàsókè pẹ̀lú rẹ̀ tí wọ́n sì ń dúró níwájú rẹ̀.
8 Porém, ele abandonou o conselho que os anciãos lhe deram, e tomou conselho com os moços que haviam crescido com ele, que se punham de pé diante dele.
9 Ó sì béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Kí ni ìmọ̀ràn yín? Báwo ni kí a ṣe dá àwọn ènìyàn wọ̀nyí tí wọ́n wí fún mi pé, ‘Mú kí àjàgà tí baba rẹ gbé lé wa kí ó fúyẹ́ díẹ̀.’ ”
9 E ele lhes disse: Que conselho me dais para que possamos voltar e responder a esse povo, o qual falou comigo, dizendo: Alivia, de alguma forma, o jugo que o teu pai pôs sobre nós?
10 Àwọn ọ̀dọ́mọdé tí ó ti dàgbà pẹ̀lú rẹ dá a lóhùn pé, “Sọ fún àwọn ènìyàn tí ó wí fún ọ wí pé, ‘Baba rẹ gbé àjàgà wúwo lórí wa, ṣùgbọ́n mú àjàgà wa fúyẹ́,’ wí fún wọn pé, ‘Ìka ọwọ́ mi kékeré, ó nípọn ju ìbàdí baba mi lọ.
10 E os moços que haviam crescido com ele falaram-lhe, dizendo: Assim responderás ao povo que falou contigo, dizendo: O teu pai fez o nosso jugo pesado, mas faz tu com que ele seja, de algum modo, mais leve para nós; assim dirás a eles: O meu dedo mínimo será mais grosso do que os lombos de meu pai.
11 Baba mi gbé àjàgà wúwo ka orí yín; èmi yóò sì tún mú kí ó wúwo sì í. Baba mi fi pàṣán nà yín; èmi yóò sì nà yín pẹ̀lú àkéekèe.’ ”
11 Pois enquanto o meu pai colocou um jugo pesado sobre vós, eu porei mais para o vosso jugo; o meu pai vos castigava com chicotes, mas eu vos castigarei com escorpiões.
12 Ní ọjọ́ kẹta Jeroboamu àti gbogbo ènìyàn sì padà sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu, gẹ́gẹ́ bí ọba ti sọ, “Ẹ padà wá sọ́dọ̀ mi ní ọjọ́ kẹta.”
12 Assim, Jeroboão, e todo o povo, vieram até Roboão no terceiro dia, como o rei ordenou, dizendo: Retornai a mim no terceiro dia.
13 Nígbà náà ni ọba dá wọn lóhùn ní ọ̀nà líle. Rehoboamu ọba sì kọ̀ ìmọ̀ràn àwọn àgbàgbà sílẹ̀,
13 E o rei respondeu-lhes grosseiramente; e o rei Roboão desprezou o conselho dos anciãos,
14 Ó sì tẹ̀lé ìmọ̀ràn àwọn ọ̀dọ́mọdé, ó sì wí pé, “Baba mi mú kí àjàgà yín wúwo; èmi yóò sì mú kí ó wúwo jù bẹ́ẹ̀ lọ. Baba mi nà yín pẹ̀lú pàṣán; èmi yóò sì nà yín pẹ̀lú àkéekèe.”
14 e respondeu a eles segundo o conselho dos jovens, dizendo: O meu pai fez o seu jugo pesado, mas eu acrescentarei a isto; o meu pai vos castigou com chicotes, mas eu vos castigarei com escorpiões.
15 Bẹ́ẹ̀ ni ọba kò sì fetísí àwọn ènìyàn, nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ni. Láti mú ọ̀rọ̀ Olúwa ṣẹ tí a ti sọ fún Jeroboamu ọmọ Nebati nípasẹ̀ Ahijah ará Ṣilo.
15 Assim, o rei não atentou ao povo; porque a causa era de Deus, para que o SENHOR pudesse cumprir a sua palavra, a qual ele falou pela mão de Aías, o silonita, a Jeroboão, o filho de Nebate.
16 Nígbà tí gbogbo Israẹli rí i wí pé ọba kọ̀ láti gbọ́ tiwọn, wọ́n sì dá ọba lóhùn wí pé,
16 E quando todo o Israel viu que o rei não quis ouvir a eles, o povo respondeu ao rei, dizendo: Que parte temos nós com Davi? E nós não temos herança alguma no filho de Jessé; cada homem para a sua tenda, ó Israel; e agora, Davi, olha pela tua própria casa. Assim, todo o Israel foi para as suas tendas.
17 Ṣùgbọ́n ní ti àwọn ọmọ Israẹli tí ń gbé ní ìlú Juda, Rehoboamu ń jẹ ọba lórí wọn.
17 Porém, quanto aos filhos de Israel que habitavam nas cidades de Judá, Roboão reinou sobre eles.
18 Ọba Rehoboamu rán Adoniramu jáde, ẹni tí ó wà ní ìkáwọ́ iṣẹ́ onírúurú, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli sọ ọ́ ní òkúta pa. Ọba Rehoboamu, gbìyànjú láti dé inú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ ó sì sálọ sí Jerusalẹmu.
18 Então, o rei Roboão enviou Adorão, que estava sobre o tributo; e os filhos de Israel o apedrejaram com pedras, de modo que morreu. Porém, o rei Roboão apressou-se em subir na sua carruagem, e fugiu para Jerusalém.
19 Bẹ́ẹ̀ ni Israẹli sì wà ní ìṣọ̀tẹ̀ lórí ilé Dafidi títí fi di òní yìí.
19 E Israel se rebelou contra a casa de Davi até este dia.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Crônicas 10, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.