2 Coríntios 8

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Pẹ̀lúpẹ̀lú, ará, àwa ń sọ fún yín ní ti oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run tí a fífún àwọn ìjọ Makedonia.
1 Taitu tuwai’inah, God ana manaw ana kabeber Kirisiyan sabuw tafaram Masedonia tema’am bi’obaiyih isan i a tur ao’owen kwanaso’ob.
2 Bí ó ti jẹ́ pé a dán wọn wò nípa ìpọ́njú, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ayọ̀ àti àìlódiwọ̀n àìní wọn ti kún àkúnwọ́sílẹ̀ nínú ọ̀rọ̀ ìlawọ́ wọn.
2 I yababan kakafih ana routobon wanawanan hirun hin, aurih sawar en baise i hai yasisir i ra’at kwanekwan kabay hiyai.
3 Nítorí mo jẹ́rìí pé gẹ́gẹ́ bí agbára wọn, àní ju agbára wọn, wọ́n ṣe é láti ìfẹ́ inú ara wọn.
3 Ayu a tur ao’owen, abisa hiya’iyai i doroh ana naniyan naatu kokomaim hiyai, baise kabay hiya’iy i tetebon.
4 Wọ́n ń fi ẹ̀bẹ̀ púpọ̀ rọ̀ wá ní ti ẹ̀bùn àtinúwá yìí, láti ba à lè ní ìpín nínú iṣẹ́ ìránṣẹ́ fún àwọn ènìyàn mímọ́.
4 Aki hifefeyani men kikiminta atibaisih kabay turin atayai. God ana sabuw Judea tema’am isah.
5 Àti èyí, kì í ṣe bí àwa tí rò rí, ṣùgbọ́n wọ́n tètè kọ́ fi àwọn fúnra wọn fún Olúwa, àti fún wá, nípa ìfẹ́ Ọlọ́run.
5 Abisa hiya’iyai i men aki anot na’atube hitayai, baise gagaminaka hiyai! Wan i hai yawas Regah isan hiya’asair, imaibo God ana kokomaim na’atube hisinaf, hai yawas aki isai hiya’asair hibaisi.
6 Tó bẹ́ẹ̀ tí àwa fi gba Titu níyànjú pé, bí ó tí bẹ̀rẹ̀ náà, bẹ́ẹ̀ ni kí ó sì parí ẹ̀bùn ọ̀fẹ́ yìí nínú yín pẹ̀lú.
6 Imih Titus aifefeyan, iti bowabow i busuruf na’atuka nabow nan naatu kwa nibaisi iti yabow ana bowabow nabow nisawar.
7 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin ti pọ̀ lóhùn gbogbo, ní ìgbàgbọ́, àti ọ̀rọ̀ àti ìmọ̀, àti nínú iṣẹ́ ìyìnrere gbogbo, àti ní ìfẹ́ yín sí wa, ẹ rí i wí pé ẹ̀yin pọ̀ sí i nínú ẹ̀bùn ọ̀fẹ́ yìí pẹ̀lú.
7 Baise bowabow tutufin etei kwa isa i karam. Kwa kwabitumitum, kwa a turamaim, kwa a ukwar rerekabamaim. Isan imih aki akokok kwanibaisi bairit yabow ana bowabow tanabow
8 Kì í ṣe nípa àṣẹ ni mo fi ń sọ ọ́, ṣùgbọ́n kí a lè rí ìdí òtítọ́ ìfẹ́ yín pẹ̀lú, nípa iṣẹ́ ìyìnrere ẹlòmíràn.
8 Ayu men roufafar ta aya’iy. Baise mi’itube sabuw ani’obaiyih hai naniyan kabay ya’inamaim nama saise kabay hinayai Kirisiyan sabuw afa hinibaisih, ayu asisinaftobon ana so’ob gewas kwa a yabow i turobe.
9 Nítorí ẹ̀yin mọ oore-ọ̀fẹ́ Olúwa wa Jesu Kristi, pé bí òun ti jẹ́ ọlọ́rọ̀ rí ṣùgbọ́n nítorí yín ó di tálákà kí a lè sọ yín di ọlọ́rọ̀ nípa àìní rẹ̀.
9 Kwa ata Regah Jesu Keriso ana manaw ana kabeber i kwaso’ob. I isan sawar etei karam, baise kwa isa na akir orot matar saise i ana bai’akiramaim kwa boro niwa’ani kwanan totobuyoy wairaf kwanamatar.
10 Àti nínú èyí ni mo fi ìmọ̀ràn mi fún yín, nítorí èyí ṣe àǹfààní fún yín, ẹ̀yin tí ó kọ́kọ́ bẹ̀rẹ̀ níwọ̀n ọdún tí ó kọjá, kì í ṣe láti ṣe nǹkan, ṣùgbọ́n láti fẹ́ pẹ̀lú.
10 Ayu au not i iti na’atube anotanot, kwa iyab iti bowabow fai komur kwabusuruf kwabowabow ana gewasin boun kwanisawaren. Kwa baitinin ana bowabow i wan kwabusuruf kwabow, men bowabow sinaf akisin. Baise takokok tanasinaf namatar.
11 Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ẹ parí ṣíṣe iṣẹ́ náà pẹ̀lú; kí ó ba à lè ṣe pé, bí ìpinnu fún ṣíṣe ti wà, bẹ́ẹ̀ ni kí ìparí sì wà láti inú agbára yín.
11 Iti bowabow kwabusuruf kwabowabow i kwanisawar, saise abistan kwakok sinaf isan kwa yayakitifuw i kwanasinaf namatar naatu abistan kwa aur ema’am i kwanayai.
12 Nítorí bí ìpinnu bá wà ṣáájú, ó jásí ìtẹ́wọ́gbà gẹ́gẹ́ bí ohun tí ènìyàn bá ní, kì í ṣe gẹ́gẹ́ bí ohun tí kò ní.
12 A naniyanamaim baitinin nama’am, o a siwar i God ebaib anayabin i aurin sawar karam, abistan i aurin sawar men kakaram i men abistan ta.
13 Nítorí èmi kò fẹ́ kí àwọn ẹlòmíràn wà ní ìrọ̀rùn, kí ó sì jẹ́ ìpọ́njú fún yín, ṣùgbọ́n pé nípa mímú dọ́gba.
13 Aki men akokok afa isah aniwa’an naham naatu kwa isa aniwa’an nafokar, baise akokok roun roun na’abara’ah kwanibaibaisbonen.
14 Ní àkókò yìí, pé kí àníṣẹ́kù yín lè ṣe déédé àìní wọn, kí àníṣẹ́kù tiwọn pẹ̀lú ba à lè ṣe déédé àìní yín, kí ìmúdọ́gba ba à lè wà.
14 Iti boun ana veya, kwa a mouramaim abistan hai kokok kwanibaisih, saise i hai mour ana veya kwa abistan kwakokok boro hinibaisi. Naatu nati kwa bairi wan kwayi anafofonin.
15 Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Ẹni tí ó kó púpọ̀ kò ní púpọ̀ jù, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó kó ìwọ̀nba kò ní kéré jù.”
15 God ana tur Buk Atamaninamaim hikirum inu’in, “Naatu orot babin yait masaw teten ebob naatu orot babin yait masaw kukuf ebob i hairi anafofonin tefafour.”
16 Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ní fún Ọlọ́run ẹni tí ó fi ìtara àníyàn kan náà yìí sí ọkàn Titu fún yín.
16 Ayu God ana merar ayiy! Iti not ta’imon ayu anotanotabe Titus kwa isa enotanot.
17 Nítorí kì í ṣe pé òun gba ọ̀rọ̀ ìyànjú wa nìkan ni; ṣùgbọ́n bí òun ti ní ìtara púpọ̀, òun tìkára rẹ̀ tọ̀ yín wá, fúnra rẹ̀.
17 Anayabin aki Titus i men abifefeyan akisin fanai bai enanamih, baise i taiyuwin ana kokomaim auman kwa nibaisimih enan.
18 Àwa ti rán arákùnrin náà pẹ̀lú rẹ̀, ìyìn ẹni tí ó wà nínú ìyìnrere yíká gbogbo ìjọ.
18 Naatu aki ai of ta i aiyun hairi tenan, ekaleisia sabuw etei i wabin tebobora’ah, anayabin tur gewasin eo ebibinan isan.
19 Kì í sì í ṣe bẹ́ẹ̀ nìkan, ṣùgbọ́n ẹni tí a tí yàn wá pẹ̀lú láti ọ̀dọ̀ ìjọ láti máa bá wa rìn kiri nínú ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ yìí, tí àwa ń ṣe ìránṣẹ́ rẹ̀ fún ògo Olúwa àti ìmúra ìtara wa.
19 Aki iti bowabow asisinaf, baise bowabow ta auman ekaleisia sabuw hirubin aki bairi anan nibaisi yabow ana bowabow anabow isan. Iti bowabow isan i Regah wabin abora’ara’ah, naatu sinafumaim abi’obaiyih.
20 Àwa ń yẹra fún èyí, kí ẹnikẹ́ni má ba à rí wí sí wa ní ti ẹ̀bùn àtinúwá yìí tí àwa pín.
20 Aki a siwar kwaya’iy akakaif gewasin men aniwa’an kakaf orot babin isai tur hina’omih.
21 Àwa ń gbèrò ohun rere, kì í ṣe níwájú Olúwa nìkan, ṣùgbọ́n níwájú ènìyàn pẹ̀lú.
21 Anayabin aki bowabow i mutufurin gewasin anabow isan i akokok, men Regah matanamaim akisin, baise sabuw matahimaim auman.
22 Àwa sì ti rán arákùnrin wa pẹ̀lú wọn, ẹni tí àwa rí dájú nígbà púpọ̀ pé ó ní ìtara nínú ohun púpọ̀, ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí ni ìtara rẹ̀ túbọ̀ pọ̀ sí i nípa ìfọkàntán ńlá tí ó ní sí yín.
22 Isan imih aki ata of tabo arubin bairi tenan, mar moumurin maiyow ef afa’ane arutubun a’itin i ebi’o’orot, i ekokok kwanekwan kwa nibaisih, anayabin kwa tafamaim i fair ebaib.
23 Bí ẹnikẹ́ni bá béèrè ẹni tí Titu jẹ́, ẹlẹgbẹ́ àti olùbáṣiṣẹ́ mi ni, nítorí yín; tàbí ní ti àwọn arákùnrin wa ni ẹnikẹ́ni ń béèrè, ìránṣẹ́ ìjọ ni wọ́n jẹ́, àti ògo Kristi.
23 Titus i ayu au of naatu ayu bowturou, ayu airi kwa anibaisi anabow, boun it tuwat na’atube. Iti orot rou’ab i ekalesia hirubin naatu Keriso wabin isan i tebobora’ara’ah.
24 Nítorí náà ẹ fi ẹ̀rí ìfẹ́ yín hàn wọ́n níwájú ìjọ, àti ìṣògo wa nítorí yín.
24 Isan imih a yabow kwani’inuw iti oro’orot hina’itin saise ekaleisia hinasu’ubih gewas naatu hinaso’ob aki gewasinawat asisinaf imih kwa isa ao abi’o’orot.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Coríntios 8, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.