2 Coríntios 2
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Nítorí náà mo tí pinnu nínú ara mí pé, èmi kì yóò tún fi ìbànújẹ́ tọ̀ yin wá.
1 Imih ayu au not ayai sawar uf men anan aninanawani yababan ta ibanak anit maiye.
2 Nítorí pé bí èmi bá mú inú yín bàjẹ́, ǹjẹ́ ta ni ẹni ti ìbá mú inú mí dùn ní àkókò tí inú mi bá bàjẹ́ bí kò ṣe ẹni tí mo ti ba nínú jẹ́?
2 Ayu kwa ana’uw kwanikwaniy yababan anabit na’at, yait boro yasisir ayu nitu?
3 Èmi sì kọ̀wé bí mo tí kọ sí yín pé, nígbà tí mo bá sì de, kí èmi má ṣe ni ìbànújẹ́ lọ́dọ̀ àwọn ti ìbá mú mi ní ayọ̀, nítorí tí mo ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú gbogbo yín, wí pé ẹ̀yin yóò jẹ́ alábápín ayọ̀ mi.
3 Ana’an iti isan ayu afef akikirum saise ayu anan na’at kwa bai yasisiru’umih kwatasisinaf i men tiyababanu. Ayu aitutumi kwa etei isa, ayu au yasisir kwa boro bairit taniyasisir.
4 Nítorí pé nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ wàhálà àti ìrora ọkàn mí ni mo ti fi ọ̀pọ̀lọpọ̀ omijé kọ̀wé sí yín; kì í ṣe nítorí kí a lè bà yín nínú jẹ́, ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin bá a lè mọ bí ìfẹ́ tí mo ní sí yín ṣe jinlẹ̀ tó.
4 Anayabin ayu dogorou babanika yababan kufutu naatu erererey auman a fef akirum, men kwa baiyababani isan, baise ti’obaiyi ayu kwa isa i dogorou babanika abiyabuwi.
5 Bí ẹnikẹ́ni bá fa ohun ìbànújẹ́ kì í ṣe èmi ni ó bà nínú jẹ́, bí kò ṣe ẹ̀yin fúnra yín, níwọ̀n ìyówù kí ó jẹ́; n kò fẹ́ sọ ọ́ lọ́nà líle jù.
5 Yait ta yababan nasisinaf na’at, men ayu akisu ebiyababanu’umih, baise kwa tutufin etei ebiyababani, ibanak men kwana’itin gagaminamih.
6 Ìyà náà tí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ti fi jẹ́ irú ènìyàn bẹ́ẹ̀ tó fún un.
6 Sabuw tutufin etei hio hibasit orot babin baimakiy ebaib nati anafofonin.
7 Kàkà bẹ́ẹ̀, ẹ̀yin ìbá kúkú dáríjì í, kí ẹ sí tù ú nínú ní gbogbo ọ̀nà, kí ìbànújẹ́ má bà á bo irú ènìyàn bẹ́ẹ̀ mọ́lẹ̀.
7 Baise gewasin ana kakafin kwananotawiy naatu koufair kwanitin, saise i boro men yababan niwanasum.
8 Nítorí náà mo bẹ̀ yín, ẹ fi ìdánilójú ìfẹ́ yín hàn sí irú ẹni náà.
8 Isan imih kwa abifefeyani, kwanau gewas naso’ob, kwa i kwabiyabuw.
9 Ìdí tí mo ṣe kọ̀wé ni kí èmi ba à lè rí ẹ̀rí dìímú nípa ìgbọ́ràn yín nínú ohun gbogbo.
9 Ayu iti fef akikirum i akokok ataso’ob gewas, karam routobon kwatisnowaten naatu bai’obaiyen etei kwatifanabow.
10 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin bá dáríjì ẹnikẹ́ni, èmi pẹ̀lú dáríjì í. Ohun tí èmi pẹ̀lú bá fi jì, nítorí tiyín ní mo fi jì níwájú Kristi.
10 Kwa orot babin ta ana kakafin kwananonotawiy na’at, ayu auman i anotanotawiy, abisa anonotawiy ana kakafin ta nama’am na’at, i Keriso nanamaim kwa wab isan anotawiy,
11 Kí Satani má ba à rẹ́ wa jẹ. Nítorí àwa kò ṣe aláìmọ́ àrékérekè rẹ̀.
11 saise Satan men karam nikubibiruwit, anayabin it taso’ob i ana yakitifuwen.
12 Ṣùgbọ́n nígbà ti mo dé Troasi láti wàásù ìyìnrere Kristi, tí mo sì rí i wí pé Olúwa ti ṣí ìlẹ̀kùn fún mi,
12 Ayu Keriso ana tur gewasin binan isan ana Troas atit naatu Regah au ef botawiy nati’imaim ata binan isan.
13 síbẹ̀ èmi kò ní àlàáfíà lọ́kàn mi, nítorí tí èmi kò rí Titu arákùnrin mi níbẹ̀. Nítorí ìdí èyí ni mo ṣe dágbére fún wọn, mo si rékọjá lọ sí Makedonia.
13 Baise ayu yababan abai, anayabin ayu teu Titus men atita’ur. Imih sabuw nati’imaim hima’am aotuturih naatu an Masedonia.
14 Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run, ẹni tí ń yọ ayọ̀ ìṣẹ́gun lórí wá nígbà gbogbo nínú Kristi, tí a sì ń fi òórùn dídùn ìmọ̀ rẹ̀ hàn nípa wa níbi gbogbo.
14 Baise God ana merar tanay! Anayabin mar etei i nawiyit Keriso ana baigegsairen isan irar yoman tatatain naatu itane God tasu’ub. boun ai ebuwayan yamurin mamarin etasasar etitit na’atube.
15 Nítorí òórùn dídùn Kristi ni àwa jẹ́ fún Ọlọ́run, nínú àwọn tí a ń gbàlà àti nínú àwọn tí ó ń ṣègbé.
15 Anayabin it i Keriso ana yamurin mamarin gewasin, God isan sibor eya’iy, nati sabuw iyab yawas hibaib naatu iyab temomorob isah.
16 Fún àwọn kan, àwa jẹ́ òórùn sí ikú, àti fún àwọn mìíràn òórùn ìyè sí ìyè. Ta ni ó ha si tọ́ fún nǹkan wọ̀nyí?
16 Sabuw iyab tekakasiy i sabuw himorobobe biyah mas yamurin kakafin, baise sabuw iyab yawas hibaib i yawas anayamurin mamarin. Iti bowabow isan yeit i karam nabow?
17 Nítorí àwa kò dàbí àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀, tí ń fi ọ̀rọ̀ Ọlọ́run ṣòwò jẹun; ṣùgbọ́n nínú òtítọ́ inú àwa ń sọ̀rọ̀ níwájú Ọlọ́run nínú Kristi gẹ́gẹ́ bí àwọn tí a rán láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá.
17 It men sabuw tutufin etei tesisinafube’emih naatu men God ana tur tabai sawar gidigidih na’atube efamaim tatobon tareremor na’atube’emih. Baise God iyunit Keriso ana bowayah tamatar, God nanamaim turobe tabibinan.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Coríntios 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.