2 Coríntios 12

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Èmi kò lè ṣàì ṣògo bí kò tilẹ̀ ṣe àǹfààní, nítorí èmi ó wà sọ nípa ìran àti ìṣípáyà ti Olúwa fihàn mí.
1 Ayu boro ana’ora’ara’at. Baise boro men imaim tanab. Ayu anarabon Regah ana i’inan ai’itah naatu abistan hirererereb ai’itah imaim anao kwananowar.
2 Èmi mọ ọkùnrin kan nínú Kristi ní ọdún mẹ́rìnlá sẹ́yìn, yálà nínú ara ni, èmi kò mọ̀; tàbí kúrò nínú ara, èmi kò mọ̀; Ọlọ́run mọ̀: a gbé irú ẹni náà lọ sí ọ̀run kẹta.
2 Ayu aso’ob kwamur etei 14 Keriso ana baitumatumayan orot ta bai au mar yen, yatetoro’ot mar ana ruf baitonin wanawanan run. Men taso’ob biyan tutufin yen o ayubin tabaratait yen. Ayu men aso’ob God akisin so’ob.
3 Bẹ́ẹ̀ ni èmi mọ irú ọkùnrin bẹ́ẹ̀, yálà ní ara ni, tàbí kúrò nínú ara ni, èmi kò mọ̀: Ọlọ́run mọ̀.
3 Ayu aso’ob nati orot, men aso’ob biyan tutufin yen o i anuninawat tabaratait yen. God akisin so’ob.
4 Pé a gbé e lọ sókè sí Paradise, tí ó sì gbọ́ ọ̀rọ̀ tí a kò sì lè sọ, tí kò tọ́ fún ènìyàn láti máa sọ.
4 I yen in Paradise, naatu nati’imaim tur nonowar i ananowarin ta, men karam boro tanao tanakubuna.
5 Nípa irú ẹni bẹ́ẹ̀ ni èmi ó máa ṣògo, ṣùgbọ́n nípa ti èmi tìkára mi èmi kì yóò ṣògo, bí kò ṣe nínú àìlera mi.
5 Imih orot nati na’atube boro isan ana’ora’ara’at, baise men ayu isou ana’ora’ara’at.
6 Nítorí pé bi èmi tilẹ̀ ń fẹ́ máa ṣògo, èmi kì yóò jẹ́ òmùgọ̀; nítorí pé èmi yóò sọ òtítọ́: ṣùgbọ́n mo kọ̀, kí ẹnikẹ́ni máa bà à fi mí pè ju ohun tí ó rí tí èmi jẹ́ lọ, tàbí ju èyí tí ó gbọ́ lẹ́nu mi,
6 Ayu anakok ana’ora’ara’at na’at, men koko’aw kwanarouw kwanao, anayabin ayu turobe ao. Baise boro men ana’ora’ara’at, anayabin ayu abistan ao kwanonowar naatu kwa’i’itin men akokok o yait ta a not yate’eka inanot wabu inabora’ah.
7 àti nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìṣípayá, kí èmi má ba à gbé ara mi ga rékọjá, a sì ti fi ẹ̀gún kan sí mi lára, ìránṣẹ́ Satani láti pọ́n mi lójú, kí èmi má bá a gbéraga rékọjá.
7 Ayu men nati ina’inan gewasih God isou iwa’an irerereb ai’itah isah ao’omih. Baise Satan ana tounamatar iyafar na biyou kokoramaim yi bai’akiru isan.
8 Nítorí nǹkan yìí ni mo ṣe bẹ Olúwa nígbà mẹ́ta pé, kí ó lé e kúrò lára mi.
8 Mar tounu Regah isan ayoyoban iti yare kakafin biyu’une tabosair isan.
9 Òun sì wí fún mi pé, “Oore-ọ̀fẹ́ mi tó fún ọ, nítorí pé a sọ agbára mi di pípé nínú àìlera.” Nítorí náà tayọ̀tayọ̀ ni èmi ó kúkú máa fi ṣògo nínú àìlera mi, kí agbára Kristi lè máa gbé inú mi.
9 Baise ayu isou eo, “Ayu au manaw kabeber o isa i karam, Ayu au fair i iyab teriririm fair ebitih.” Isan imih ayu boro ana’ora’ara’at aniyasisir gagamin na’in ayu ariririm isan, saise Keriso ana fair tafu namara’at.
10 Nítorí náà èmi ní inú dídùn nínú àìlera gbogbo, nínú ẹ̀gàn gbogbo, nínú àìní gbogbo, nínú inúnibíni gbogbo, nínú wàhálà gbogbo nítorí Kristi. Nítorí nígbà tí mo bá jẹ́ aláìlera, nígbà náà ni mo di alágbára.
10 Nati isan Keriso wabinamaim ariririm baise abiyasisir, tur kakafin, bowabow fokarih, yawas o morob, yare ta ta fokarih. Anamaramaim ariririm ayu fair abaib.
11 Mo di òmùgọ̀ nípa ṣíṣògo; ẹ̀yin ní ó fi ipá mú mi ṣe é, nítorí tí ó tọ́ tí ẹ bá yìn mí, nítorí tí èmi kò rẹ̀yìn lóhunkóhun sí àwọn àgbà aposteli bí èmi kò tilẹ̀ jámọ́ nǹkan kan.
11 Ayu au sinaf i boun hai not meyemeye na’atube, baise kwa kwa’ora’ahu ayu anasinaf. Kwa karam ayu isou boro baibasit tur kwatao, anayabin ayu i men kafa’imo orot fairu boun iti tounamatar hai fair gagamih na’atube, ayu i yabin en.
12 Ohun kan tí ó ṣe àmì aposteli, iṣẹ́ ìyanu àti iṣẹ́ agbára ni wọ́n ṣe ní àárín yín pẹ̀lú sùúrù tó ga.
12 Anamaramaim ayu bairit tama’am, ayu yataunub naatu ina’inan, men tisinaf emamatar asinaf himatar naatu baifofofor fairih maiyow kwa wanawanamaim asinaf himatar, iti ebiturobe ayu i kwa a turabarayan.
13 Nítorí nínú kín ni ohun tí ẹ̀yin ṣe rẹ̀yìn sí ìjọ mìíràn, bí kò ṣe ní ti pé èmi fúnra mi kó jẹ́ oníyọnu fún yín? Ẹ dárí àṣìṣe yìí jì mí.
13 Ayu au sinaf mi’itube isa asisinaf i na’atube ekalesia sabuw etei isah a sisinaf. Ana veya ta ayu men kafa’imo ubar aitimih kabay yai’in ayu baibaisu isan. Abistan kakafin asisinaf kwaninatbuhuruwu.
14 Kíyèsi i, ìgbà kẹta yìí ni mo múra tan láti tọ̀ yín wá, èmi kì yóò sì jẹ́ oníyọnu fún yín nítorí tí èmi kò wá nǹkan yín, bí kò ṣe ẹ̀yin fúnra yín; nítorí tí kò tọ́ fún àwọn ọmọ láti máa to ìṣúra jọ fún àwọn òbí wọn, bí kò ṣe àwọn òbí fún àwọn ọmọ wọn.
14 Iti boun i mar baitounin ayu abobogaigiwas anan kwa aninanawani. Ayu au naa isan boro men aniwa’an nafokar anayabin ayu men akokok kwa a sawar, ayu akokok i kwa. Kek i men karam hinah tamah hinakaifih baise hinah tamah i karam kek hinakaifih
15 Èmi ó sì fi ayọ̀ ná ohun gbogbo tí mo bá ní, èmi ó sì ná ara mi fún ọkàn yín nítòótọ́; bí mo bá fẹ́ yín lọ́pọ̀lọ́pọ̀, ó ha tọ́ kí ẹ̀yin kí ó fẹ́ràn mi díẹ̀ bí?
15 Ayu i abiyasisir gagamin na’in, ayu au sawar etei kwa isa abi’asrouwen naatu au fair etei anit kwa a baibais isan. Kwa isa ayu abi yabow kwanekwan, naatu aisimamih ayu isou men kwabiyabow gewas?
16 Ṣùgbọ́n ó dára bẹ́ẹ̀ tí èmi kò dẹ́rùbà yín, ṣùgbọ́n bí ọlọ́gbọ́n ènìyàn, èmi ń fi ọwọ́ ẹ̀rọ̀ mú yín.
16 Isan imih iti tur ao i kwabibasit, ayu men kwa bit ait. Baise sabuw afa boro ayu isou hinao, ayu i ah atain abifufuwen.
17 Èmi ha rẹ́ yín jẹ nípa ẹnikẹ́ni nínú àwọn tí mo rán sí yín bi?
17 Ayu oro’orot aiyunih hinanamaim ayu kwa abainuwi?
18 Mo bẹ Titu, mo sì rán arákùnrin kan pẹ̀lú rẹ̀; Titu ha rẹ́ yín jẹ bí? Nípa ẹ̀mí kan náà kọ́ ni àwa rìn bí? Ọ̀nà kan náà kọ́ ni àwa tọ̀ bí?
18 Ayu Titus aifefeyan i boro tuwat ta hairi hinan kwa hininanawani.
19 Ẹ̀yin ha rò pé àwa ń sọ nǹkan wọ̀nyí láti gbèjà ara wa níwájú yín bí? Ní iwájú Ọlọ́run ni àwa ń sọ̀rọ̀ nínú Kristi; ṣùgbọ́n àwa ń ṣe ohun gbogbo, olùfẹ́ ọ̀wọ́n, láti gbé yín ró ni.
19 Kwa a not iti na’atube kwanotanot, aki mar etei asisinaftobon aki kwa anarufafari. Aiyabin! Keriso bibinanube aki abibinan, i aki awaimaim eo re God nanamaim aki tur ao’orerereb. Are au ofonah, sawar etei asisinaf, i kwa nibaisi isan.
20 Nítorí ẹ̀rù ń bà mí pé, nígbà tí mo bá dé, èmi kì yóò bá yín gẹ́gẹ́ bí irú èyí tí mo fẹ́, àti pé ẹ̀yin yóò sì rí mi gẹ́gẹ́ bí irú èyí tí ẹ̀yin kò fẹ́: kí ìjà, owú jíjẹ, ìbínú, ìpinyà, ìṣọ̀rọ̀-ẹni-lẹ́yìn, òfófó, ìgbéraga, ìrúkèrúdò, má ba à wà.
20 Ayu abirubir ana maramaim anan kwa anabinanawani, kwa a itinin i men ayu anotanot na’atube ana itimih naatu ayu kwana i’itu men kwa kwanotanot na’atube kwana itu. Ayu biyau ekakameyaw anayabin nati’imaim gamin ema’am, bobowen, yaso’ar etit erara’iy, kabat, bai’i’iyab, rarikasar, naatu hai ma men gewasih.
21 Àti nígbà tí mo bá sì padà dé, kí Ọlọ́run mí má bà à rẹ̀ mí sílẹ̀ lójú yín, àti kí èmi má ba à sọkún nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn tí ó tí ṣẹ̀ náà tí kò sì ronúpìwàdà ẹ̀ṣẹ̀ ìwà èérí, àgbèrè, àti wọ̀bìà tí wọ́n ti hù.
21 Ayu abirubir anamaramaim anan biya ana titit maiye, kwa namaim ayu au God boro au yawas nayara’iy naham, naatu sabuw moumurih marasika kakafih hisisinaf isan boro anarererey. Anayabin kwa i dogoroh kato men kwainatbuhuruwen, naatu baiwa’an ana bainikinik. I boro’ika kwama kwabi’a’it.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 2 Coríntios 12, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.