1 Samuel 3
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Samuẹli ọmọkùnrin náà ṣe òjíṣẹ́ níwájú Olúwa ní abẹ́ Eli. Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ọ̀rọ̀ Olúwa ṣọ̀wọ́n: kò sì sí ìran púpọ̀.
1 E o menino Samuel ministrava ao SENHOR diante de Eli. E a palavra do SENHOR era preciosa naqueles dias: não havia nenhuma visão aberta.
2 Ní alẹ́ ọjọ́ kan Eli ẹni tí ojú rẹ̀ ti bẹ̀rẹ̀ sí di aláìlágbára, tí kò sì ríran dáradára, ó dùbúlẹ̀ ní ipò rẹ̀ bi ti àtẹ̀yìnwá.
2 E sucedeu, naqueles dias, quando Eli estava deitado em seu lugar, e os seus olhos começavam a ficar tão turvos que ele não conseguia mais enxergar;
3 Nígbà tí iná kò tí ì kú Samuẹli dùbúlẹ̀ nínú tẹmpili Olúwa, níbi tí àpótí Olúwa gbé wà.
3 e antes da lâmpada de Deus se apagar no templo do SENHOR, onde estava a arca de Deus, e Samuel estava deitado para dormir;
4 Nígbà náà ni Olúwa pe Samuẹli.
4 que o SENHOR chamou Samuel; e ele respondeu: Aqui estou eu.
5 Ó sì sáré lọ sí ọ̀dọ̀ Eli ó sì wí pé, “Èmi nìyí nítorí pé ìwọ pè mí.”
5 E ele correu até Eli, e disse: Aqui estou eu, pois me chamaste. E ele disse: Não chamei, deita-te novamente. E ele foi e se deitou.
6 Olúwa sì tún pè é, “Samuẹli!” Samuẹli tún dìde ó tọ Eli lọ, ó sì wí pé, “Èmi nìyìí, nítorí tí ìwọ pè mí.”
6 E o SENHOR chamou mais uma vez: Samuel. E Samuel se levantou e foi até Eli, e disse: Aqui estou eu, pois tu me chamaste. E ele respondeu: Não chamei, meu filho; deita-te novamente.
7 Ní àkókò yìí Samuẹli kò tí ì mọ̀ Olúwa: bẹ́ẹ̀ ni a kò sì tí ì fi ọ̀rọ̀ Olúwa hàn án.
7 Ora, Samuel ainda não conhecia o SENHOR, nem ainda a palavra do SENHOR lhe havia sido revelada.
8 Olúwa pe Samuẹli ní ìgbà kẹta, Samuẹli sì tún dìde, ó sì lọ sọ́dọ̀ Eli ó sì wí pé, “Èmi nìyìí; nítorí tí ìwọ pè mí.”
8 E o SENHOR chamou Samuel novamente, pela terceira vez. E ele se levantou e foi até Eli, e disse: Aqui estou eu, pois tu me chamaste. E Eli percebeu que o SENHOR havia chamado a criança.
9 Nítorí náà Eli sọ fún Samuẹli, “Lọ kí o lọ dùbúlẹ̀. Tí o bá sì pè ọ́, sọ wí pé, ‘Máa wí, Olúwa nítorí tí ìránṣẹ́ rẹ ń gbọ́.’ ” Bẹ́ẹ̀ ni Samuẹli lọ, ó sì lọ dùbúlẹ̀ ní ààyè rẹ̀.
9 Por isso disse Eli a Samuel: Vai, deita-te; e sucederá que, se ele te chamar, tu dirás: Fala, SENHOR; pois o teu servo ouve. Assim, Samuel foi e se deitou em seu lugar.
10 Olúwa wá, ó sì dúró níbẹ̀, ó pè é bí ó ṣe pè é ní ìgbà tí ó kọjá, “Samuẹli! Samuẹli!”
10 E o SENHOR veio, e levantou-se, e chamou, como das outras vezes: Samuel, Samuel. Então, Samuel respondeu: Fala, pois teu servo ouve.
11 Olúwa sọ fún Samuẹli pé, “Wò ó, èmi ṣetán láti ṣe ohun kan ní Israẹli tí yóò jẹ́ kí etí gbogbo ènìyàn tí ó gbọ́ ọ já gooro.
11 E o SENHOR disse a Samuel: Eis que uma coisa farei em Israel, diante da qual zumbirão ambos os ouvidos de cada um que a ouvir.
12 Ní ìgbà náà ni èmi yóò mú ohun gbogbo tí mo ti sọ sí ilé Eli ṣẹ láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin.
12 Naquele dia cumprirei contra Eli todas as coisas que mencionei a respeito da sua casa: Quando eu começar, também levarei a cabo.
13 Nítorí èmi sọ fún un pé, Èmi yóò ṣe ìdájọ́ fún ilé rẹ̀ títí láé nítorí ìwà ẹ̀ṣẹ̀ wọn tí òun mọ̀ nípa rẹ̀ nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ sọ ọ̀rọ̀-òdì, òun kò sì dá wọn lẹ́kun.
13 Pois eu lhe disse que julgarei sua casa para sempre pela iniquidade que ele conhece; porque os seus filhos fizeram-se vis, e ele não os refreou.
14 Nítorí náà, mo búra sí ilé Eli, ‘Ìwà ẹ̀ṣẹ̀ ilé Eli ni a kì yóò fi ẹbọ tàbí ọrẹ mú kúrò láéláé.’ ”
14 E, por isso, jurei à casa de Eli, que a iniquidade da casa de Eli não será purgada com sacrifício, tampouco com oferta, para sempre.
15 Samuẹli dùbúlẹ̀ títí di òwúrọ̀ nígbà náà ó sì ṣí ìlẹ̀kùn ilé Olúwa, ó sì bẹ̀rù láti sọ ìran náà fún Eli.
15 E Samuel permaneceu deitado até a manhã, e abriu as portas da casa do SENHOR. E Samuel temeu apresentar a visão a Eli.
16 Ṣùgbọ́n Eli pè é, ó sì wí pé, “Samuẹli, ọmọ mi.”
16 Então Eli chamou Samuel, e disse: Samuel, meu filho. E ele respondeu: Aqui estou eu.
17 Eli béèrè pé, “Kín ni ohun tí ó sọ fún ọ?” “Má ṣe fi pamọ́ fún mi. Kí Ọlọ́run mi ṣe bẹ́ẹ̀ sí ọ àti jù bẹ́ẹ̀ lọ pẹ̀lú, bí ìwọ bá fi ohunkóhun tí ó wí fún ọ pamọ́ fún mi.”
17 E ele disse: Que coisa é que o SENHOR te disse? Rogo-te que não a ocultes de mim; que Deus assim te faça, e ainda mais, se ocultares de mim qualquer coisa de todas as coisas que ele te disse.
18 Samuẹli sọ gbogbo rẹ̀ fún un, kò sì fi ohun kankan pamọ́ fún un. Nígbà náà Eli wí pé, “Òun ni Olúwa; jẹ́ kí ó ṣe ohun tí ó dára ní ojú rẹ̀.”
18 E Samuel lhe contou todo detalhe e dele nada ocultou. E ele disse: É o SENHOR; que Ele faça o que lhe parecer bem.
19 Olúwa wà pẹ̀lú Samuẹli bí ó ṣe ń dàgbà, kò sì jẹ́ kí ọ̀kan nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ kùnà.
19 E Samuel cresceu, e o SENHOR estava com ele, e não permitiu que nenhuma das suas palavras caísse por terra.
20 Gbogbo Israẹli láti Dani títí dé Beerṣeba mọ̀ pé a ti fa Samuẹli kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bí wòlíì Olúwa.
20 E todo o Israel, desde Dã até Berseba, soube que Samuel fora estabelecido para ser um profeta do SENHOR.
21 Olúwa sì bẹ̀rẹ̀ sí ní fi ara hàn án ní Ṣilo, nítorí Olúwa ti fi ará hàn án fún Samuẹli ní Ṣilo nípa ọ̀rọ̀ Olúwa.
21 E o SENHOR apareceu novamente em Siló; pois o SENHOR revelou-se a Samuel em Siló pela palavra do SENHOR.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Samuel 3, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.