1 Samuel 2

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Hana sì gbàdúrà pé,
1 E Ana orou, e disse: Meu coração exulta no ­SENHOR, meu chifre é exaltado no ­SENHOR; minha boca é ampliada sobre os meus inimigos, porque eu exulto na tua salvação.
2 “Kò sí ẹni tí ó mọ́ bi Olúwa;
2 Não há nenhum santo como o ­SENHOR; pois não há nenhum além de ti; tampouco há uma rocha como o nosso Deus.
3 “Má ṣe halẹ̀;
3 Não faleis mais com tamanha soberba; não deixeis que a arrogância saia da vossa boca; pois o ­SENHOR é um Deus de conhecimento, e por ele as ações são medidas.
4 “Ọ̀run àwọn alágbára ti ṣẹ́,
4 Os arcos dos homens poderosos são quebrados, e os que são pisoteados são cingidos com vigor.
5 Àwọn tí ó yọ̀ fún oúnjẹ ti fi ara wọn ṣe alágbàṣe,
5 Os que estavam fartos alugaram-se a si mesmos por pão; e os que estavam famintos cessaram; de modo que a estéril deu à luz sete; e aquela que tem muitos filhos é enfraquecida.
6 “Olúwa pa ó sì sọ di ààyè;
6 O ­SENHOR mata, e faz viver; ele faz descer ao sepulcro, e faz subir.
7 Olúwa sọ di tálákà; ó sì sọ di ọlọ́rọ̀;
7 O ­SENHOR empobrece, e enriquece; ele traz abaixo e exalta.
8 Ó gbé tálákà sókè láti inú erùpẹ̀ wá,
8 Ele ergue o pobre do pó, e levanta o mendigo do monte de estrume, para colocá-los entre os príncipes, e fazê-los herdar o trono da glória; pois os pilares da terra são do ­SENHOR, e ele estabeleceu o mundo sobre eles.
9 Yóò pa ẹsẹ̀ àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ mọ́,
9 Ele guardará os pés dos seus santos, e os ímpios serão silenciados na escuridão; pois pela força nenhum homem prevalecerá.
10 A ó fọ́ àwọn ọ̀tá Olúwa túútúú;
10 Os adversários do ­SENHOR serão quebrados em pedaços; do céu ele trovejará sobre eles; o ­SENHOR julgará as extremidades da terra; e dará força ao seu rei, e exaltará o chifre do seu ungido.
11 Elkana sì lọ sí Rama, sí ilé rẹ̀, ọmọ náà sì ń ṣe ìránṣẹ́ fún Olúwa níwájú Eli àlùfáà.
11 E Elcana foi a Ramá, para a sua casa. E a criança ministrava ao ­SENHOR diante de Eli, o sacerdote.
12 Àwọn ọmọ Eli sì jẹ́ ọmọ Beliali; wọn kò mọ Olúwa.
12 Ora, os filhos de Eli eram filhos de Belial; eles não conheciam o ­SENHOR.
13 Iṣẹ́ àwọn àlùfáà pẹ̀lú àwọn ènìyàn ni pé nígbà tí ẹnìkan bá ṣe ìrúbọ, ìránṣẹ́ àlùfáà á dé, nígbà tí ẹran náà bá ń hó lórí iná, pẹ̀lú ọ̀pá-ẹran náà oníga mẹ́ta ní ọwọ́ rẹ̀.
13 E o costume dos sacerdotes com o povo era que, quando qualquer homem oferecesse sacrifício, o servo do sacerdote vinha, enquanto a carne estava em fervura, com um gancho para carnes de três dentes em sua mão;
14 Òun a sì fi gún inú apẹ, tàbí àgé tàbí ọpọ́n, tàbí ìkòkò, gbogbo èyí tí ọ̀pá-ẹran oníga náà bá mú wá sí òkè, àlùfáà á mú un fún ara rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ń ṣe sí gbogbo Israẹli tí ó wá sí ibẹ̀ ní Ṣilo.
14 e ele o lançava na panela, ou tacho, ou caldeirão, ou pote; tudo o que o gancho de carne trazia para o alto, o sacerdote tomava para si. Assim faziam em Siló a todos os israelitas que para lá iam.
15 Pẹ̀lú, kí wọn tó sun ọ̀rá náà, ìránṣẹ́ àlùfáà á dé, á sì wí fún ọkùnrin tí ó ń ṣe ìrúbọ pé, “Fi ẹran fún mi láti sun fún àlùfáà; nítorí tí kì yóò gba ẹran sísè lọ́wọ́ rẹ, bí kò ṣe tútù.”
15 Também antes de eles queimarem a gordura, o servo do sacerdote vinha, e dizia ao homem que sacrificava: Dá carne para o sacerdote assar; pois ele não terá carne mal cozida de ti, porém crua.
16 Bí ọkùnrin náà bá sì wí fún un pé, “Jẹ́ kí wọn ó sun ọ̀rá náà nísinsin yìí, kí o sì mú iyekíye tí ọkàn rẹ̀ bá fẹ́,” nígbà náà ni yóò dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, ṣùgbọ́n kí ìwọ ó fi í fún mi nísinsin yìí, bí kó ṣe bẹ́ẹ̀, èmi ó fi agbára gbà á.”
16 E se qualquer homem lhe dissesse: Que não falhem em queimar a gordura neste momento, e, depois, toma tudo quanto desejar a tua alma; ele, então, responder-lhe-ia: Não; mas tu ma darás agora; se não, tomá-la-ei à força.
17 Ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì tóbi gidigidi níwájú Olúwa: nítorí tí àwọn ènìyàn kórìíra ẹbọ Olúwa.
17 Por isso o pecado dos jovens era muito grande diante do ­SENHOR; pois os homens abominavam a oferta do ­SENHOR.
18 Ṣùgbọ́n Samuẹli ń ṣe ìránṣẹ́ níwájú Olúwa, ọmọdé, ti a wọ̀ ní efodu ọ̀gbọ̀.
18 Porém, Samuel ministrava diante do ­SENHOR, sendo criança, cingido com um éfode de linho.
19 Pẹ̀lúpẹ̀lú, ìyá rẹ̀ máa ń dá aṣọ ìlekè péńpé fún un, a sì máa mú wá fún un lọ́dọọdún, nígbà tí ó bá bá ọkọ rẹ̀ gòkè wá láti ṣe ìrúbọ ọdún.
19 Ademais, a sua mãe lhe fazia uma pequena túnica, e lha trazia de ano a ano, quando ela subia com o seu marido para oferecer o sacrifício anual.
20 Eli súre fún Elkana àti aya rẹ̀ pé, “Kí Olúwa fún ọ ní irú-ọmọ láti ara obìnrin yìí wá, nítorí ẹ̀bùn tí ó béèrè tí ó sì tún fún Olúwa.” Wọ́n sì lọ sí ilé wọn.
20 E Eli abençoava Elcana e sua esposa, e dizia: Que o ­SENHOR te dê semente desta mulher pelo empréstimo que é emprestado ao ­SENHOR. E eles seguiam para a sua própria casa.
21 Olúwa si bojú wo Hana, ó sì lóyún, ó bí ọmọkùnrin mẹ́ta àti ọmọbìnrin méjì. Samuẹli ọmọ náà sì ń dàgbà níwájú Olúwa.
21 E o ­SENHOR visitou Ana, de modo que ela concebeu, e deu à luz três filhos e duas filhas. E o menino Samuel crescia diante do ­SENHOR.
22 Eli sì di arúgbó gidigidi, ó sì gbọ́ gbogbo èyí ti àwọn ọmọ rẹ̀ ṣe sí gbogbo Israẹli; àti bi wọ́n ti máa ń bá àwọn obìnrin sùn, tí wọ́n máa ń péjọ ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ àjọ.
22 Ora, Eli era muito velho, e ouvia tudo o que os seus filhos faziam a todo o Israel; e como eles se deitavam com as mulheres que se reuniam à porta do tabernáculo da congregação.
23 Ó sì wí fún wọn pé, kí ni ó ti ri “Èétirí tí èmi fi ń gbọ́ irú nǹkan bẹ́ẹ̀ sí yín? Nítorí tí èmi ń gbọ́ iṣẹ́ búburú yín láti ọ̀dọ̀ gbogbo ènìyàn.
23 E ele lhes disse: Por que fazeis vós tais coisas? Pois ouço de todo este povo sobre o vosso mal proceder.
24 Bẹ́ẹ̀ kọ́ ẹ̀yin ọmọ mi, nítorí kì ṣe ìròyìn rere èmi gbọ́; ẹ̀yin mú ènìyàn Olúwa dẹ́ṣẹ̀.
24 Não, filhos meus; pois não ouço nenhum bom relato: Vós fazeis com que o povo do ­SENHOR transgrida.
25 Bí ẹnìkan bá ṣẹ̀ sí ẹnìkejì, onídàájọ́ yóò ṣe ìdájọ́ rẹ̀: ṣùgbọ́n bí ẹnìkan bá ṣẹ̀ sí Olúwa, ta ni yóò bẹ̀bẹ̀ fún un?” Wọn kò sì fi etí sí ohùn baba wọn, nítorí tí Olúwa ń fẹ́ pa wọ́n.
25 Se um homem pecar contra outro, o juiz o julgará; mas se um homem pecar contra o ­SENHOR, quem intercederá por ele? Não obstante, eles não atentaram à voz do seu pai, porque o ­SENHOR os mataria.
26 Ọmọ náà Samuẹli ń dàgbà, ó sì rí ojúrere lọ́dọ̀ Olúwa, àti ènìyàn pẹ̀lú.
26 E o menino Samuel cresceu, e tinha o favor tanto do ­SENHOR, como também dos homens.
27 Ènìyàn Ọlọ́run kan tọ Eli wá, ó sì wí fún un pé, “Báyìí ni Olúwa wí, ‘Èmi fi ara mi hàn ní gbangba fún ilé baba rẹ, nígbà tí wọ́n ń bẹ ní Ejibiti nínú ilé Farao.
27 E veio um homem de Deus até Eli, e lhe disse: Assim diz o ­SENHOR: Não apareci eu, claramente, à casa do teu pai, quando eles estavam no Egito, na casa de Faraó?
28 Èmi sì yàn án kúrò láàrín gbogbo ẹ̀yà Israẹli láti jẹ́ àlùfáà mi, láti rú ẹbọ lórí pẹpẹ mi, láti fi tùràrí jóná, láti wọ efodu níwájú mi, èmi sì fi gbogbo ẹbọ tí ọmọ Israẹli máa ń fi iná sun fún ìdílé baba rẹ̀.
28 E eu o escolhi de todas as tribos de Israel para ser meu sacerdote, para ofertar sobre o meu altar, para queimar incenso, para vestir um éfode diante de mim. E eu dei à casa do teu pai todas as ofertas dos filhos de Israel feitas pelo fogo.
29 Èéha ṣe tí ẹ̀yin fi tàpá sí ẹbọ àti ọrẹ mi, tí mo pàṣẹ ní ibùjókòó mi, ìwọ sì bu ọlá fún àwọn ọmọ rẹ jù mí lọ, tí ẹ sì fi gbogbo àṣàyàn ẹbọ Israẹli àwọn ènìyàn mi mú ara yín sanra.’
29 Por que chutais o meu sacrifício e a minha oferta, que tenho ordenado em minha habitação; e honras os teus filhos acima de mim, para fazer-vos gordos com a principal de todas as ofertas de Israel, meu povo?
30 “Nítorí náà Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí pé, ‘Èmi ti wí nítòótọ́ pé, ilé rẹ àti ilé baba rẹ, yóò máa rìn níwájú mi títí.’ Ṣùgbọ́n nísinsin yìí Olúwa wí pé, ‘Kí á má rí i! Àwọn tí ó bú ọlá fún mi ni èmi yóò bu ọlá fún, àti àwọn tí kò kà mí sí ni a ó sì ṣe aláìkàsí.
30 Por isso o ­SENHOR Deus de Israel diz: Eu disse, verdadeiramente, que a tua casa, e a casa de teu pai, deveria andar diante de mim para sempre; mas, agora, o ­SENHOR diz: Esteja isso longe de mim; pois honrarei os que me honram, e aqueles que me desprezam serão pouco estimados.
31 Kíyèsi i, àwọn ọjọ́ ń bọ̀ tí èmi ó gé agbára rẹ kúrò, àti agbára baba rẹ, tí kì yóò sí arúgbó kan nínú ilé rẹ.
31 Eis que vêm dias em que cortarei o teu braço, e o braço da casa do teu pai, e não haverá sequer um velho na tua casa.
32 Ìwọ yóò rí wàhálà ti Àgọ́, nínú gbogbo ọlá tí Ọlọ́run yóò fi fún Israẹli; kì yóò sí arúgbó kan nínú ilé rẹ láéláé.
32 E tu verás um inimigo na minha habitação, em toda a riqueza que Deus dará a Israel; e não haverá um velho sequer na tua casa para sempre.
33 Ọkùnrin tí ó jẹ́ tìrẹ, tí èmi kì yóò gé kúrò ní ibi pẹpẹ mi ni a ó dá sí láti sọkún yọ lójú àti láti banújẹ́. Ṣùgbọ́n gbogbo irú-ọmọ ilé rẹ̀ ni a ó fi idà pa ní ààbọ̀ ọjọ́ wọn.
33 E o teu homem, a quem não cortarei do meu altar, será para consumir os teus olhos, e para afligir o teu coração; e todo o incremento da tua casa morrerá na flor de sua idade.
34 “ ‘Kí ni ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ọmọ ọkùnrin rẹ̀ méjèèjì, Hofini àti Finehasi, yóò jẹ́ àmì fún ọ—àwọn méjèèjì yóò kú ní ọjọ́ kan náà.
34 E isto será um sinal para ti, que sobrevirá aos teus dois filhos, sobre Hofni e Fineias: Em um dia morrerão ambos.
35 Èmi yóò dìde fún ara mi láti gbé àlùfáà olódodo dìde fún ara mi, ẹni tí yóò ṣe gẹ́gẹ́ bí ohun tí ó wà ní ọkàn mi àti inú mi. Èmi yóò fi ẹsẹ̀ ilé rẹ̀ múlẹ̀ gbọningbọnin òun yóò sì ṣe òjíṣẹ́ níwájú ẹni òróró mi ní ọjọ́ gbogbo.
35 Eu levantarei para mim um sacerdote fiel, que fará de acordo com aquilo que está no meu coração e na minha mente; e para ele edificarei uma casa segura; e ele andará diante do meu ungido para sempre.
36 Nígbà náà olúkúlùkù ẹnikẹ́ni tí ó bá kù ní ìdílé yín, yóò jáde wá yóò sì foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀ nítorí ẹyọ fàdákà àti nítorí èépá àkàrà àti ẹ̀bẹ̀ pé, “Jọ̀wọ́ yàn mí sí ọ̀kan nínú iṣẹ́ àwọn àlùfáà, kí èmi kí ó le máa rí oúnjẹ jẹ.” ’ ”
36 E sucederá que, todo aquele que for deixado na tua casa virá e se agachará diante dele por um pedaço de prata e um bocado de pão, e dirá: Põe-me, rogo-te, em um dos ofícios dos sacerdotes, para que eu possa comer um pedaço de pão.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Samuel 2, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.