1 Reis 18

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Ó sì ṣe, lẹ́yìn ọjọ́ púpọ̀, ní ọdún kẹta, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Elijah wá pé, “Lọ, kí o sì fi ara rẹ̀ hàn fún Ahabu, èmi yóò sì rọ òjò sórí ilẹ̀.”
1 E sucedeu, depois de muitos dias, que a palavra do SENHOR veio a Elias no terceiro ano, dizendo: Vai, mostra-te a Acabe; e eu enviarei chuva sobre a terra.
2 Bẹ́ẹ̀ ni Elijah lọ fi ara rẹ̀ han Ahabu.
2 E foi Elias apresentar-se a Acabe. E houve uma fome extrema em Samaria.
3 Ahabu sì ti pe Obadiah, ẹni tí ń ṣe olórí ilé rẹ̀. Obadiah sì bẹ̀rù Olúwa gidigidi.
3 E Acabe chamou Obadias, o qual era o governador da sua casa. (Ora, Obadias temia muitíssimo ao SENHOR;
4 Nígbà tí Jesebeli sì ń pa àwọn wòlíì Olúwa kúrò, Obadiah sì mú ọgọ́rùn-ún wòlíì, ó sì fi wọ́n pamọ́ sínú ihò òkúta, àádọ́ta ní ihò kọ̀ọ̀kan, ó sì fi àkàrà pẹ̀lú omi bọ́ wọn.
4 porque foi assim, quando Jezabel extirpou os profetas do SENHOR, que Obadias tomou uma centena de profetas, e ocultou-lhes em dois grupos de cinquenta em uma caverna, e os alimentou com pão e água.)
5 Ahabu sì ti wí fún Obadiah pé, “Lọ sí gbogbo ilẹ̀ sí orísun omi gbogbo àti sí ilẹ̀ gbogbo. Bóyá àwa lè rí koríko láti gba àwọn ẹṣin àti àwọn ìbáaka là, kí a má bá à ṣòfò àwọn ẹranko pátápátá.”
5 E Acabe disse a Obadias: Adentra a terra, a todas as fontes de água, e a todos os ribeiros; porventura podemos achar erva para salvar a vida dos cavalos e das mulas, para que não percamos todos os animais.
6 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì pín ilẹ̀ tí wọ́n fẹ́ dé láàrín ara wọn, Ahabu gba ọ̀nà kan lọ, Obadiah sì gba ọ̀nà mìíràn lọ.
6 Assim, eles dividiram a terra entre si, para atravessá-la. Acabe seguiu por um caminho sozinho, e Obadias seguiu por outro caminho sozinho.
7 Bí Obadiah sì ti ń rìn lọ, Elijah sì pàdé rẹ̀. Obadiah sì mọ̀ ọ́n, ó dojúbolẹ̀, ó sì wí pé, “Ǹjẹ́ ìwọ ni nítòótọ́, Elijah, olúwa mi?”
7 E, enquanto Obadias estava no caminho, eis que Elias o encontrou; e ele o reconheceu, prostrou-se sobre a sua face, e disse: És tu aquele meu senhor, Elias?
8 Elijah sì dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, lọ kí o sọ fún olúwa rẹ pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’ ”
8 E ele respondeu: Sou eu; vai e conta ao teu senhor: Eis que Elias está aqui.
9 Obadiah sì béèrè pé, “Ẹ̀ṣẹ̀ kí ni mo ha dá tí ìwọ fi ń fi ìránṣẹ́ rẹ lé Ahabu lọ́wọ́ láti pa?
9 E ele disse: No que tenho eu pecado para que tu queiras entregar o teu servo na mão de Acabe, para me matar?
10 Mo mọ̀ dájú pé bí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti ń bẹ, kò sí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan tí olúwa mi kò ti rán ènìyàn lọ láti wò ọ́. Àti nígbà tí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan bá wí pé o kò sí, òun a sì mú kí wọ́n búra wí pé wọn kò rí ọ.
10 Como vive o SENHOR teu Deus, não há nação ou reino, para onde o meu senhor não tenha me enviado a te procurar; e dizendo eles: Aqui não está, então fazia jurar os reinos e nações, que não te haviam encontrado.
11 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìwọ wí fún mi pé kí n lọ sọ́dọ̀ olúwa mi, kí n sì wí pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’
11 E, agora, tu dizes: Vai e conte ao teu senhor: Eis que Elias está aqui.
12 Èmi kò sì mọ ibi tí ẹ̀mí Olúwa yóò gbé ọ lọ nígbà tí mo bá fi ọ́ sílẹ̀. Bí mo bá lọ, tí mo sì sọ fún Ahabu, tí kò sì rí ọ, òun a sì pa mí. Síbẹ̀ èmi ìránṣẹ́ rẹ bẹ̀rù Olúwa láti ìgbà èwe mi wá.
12 E sucederá, tão logo eu parta de ti, que o Espírito do SENHOR te carregará para onde eu não sei; e, assim, quando eu vier e contar a Acabe, e ele não conseguir te encontrar, me matará; mas eu, o teu servo, temo o SENHOR desde a minha mocidade.
13 Ṣé Olúwa mi kò ha ti gbọ́ ohun tí mo ṣe nígbà tí Jesebeli ń pa àwọn wòlíì Olúwa? Mo fi ọgọ́rùn-ún wòlíì Olúwa pamọ́ sínú ihò òkúta méjì, àràádọ́ta ní ọ̀kọ̀ọ̀kan, mo sì fi omi àti oúnjẹ bọ́ wọn.
13 Não foi contado ao meu senhor o que eu fiz quando Jezabel matou os profetas do SENHOR, como eu ocultei uma centena de homens dos profetas do SENHOR em dois grupos de cinquenta em uma caverna, e os alimentei com pão e água?
14 Ìwọ sì sọ fún mi nísinsin yìí pé, kí n tọ olúwa mi lọ pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’ Òun a sì pa mí!”
14 E, agora, dizes: Vai e conta ao teu senhor: Eis que Elias está aqui; e ele me matará.
15 Elijah sì wí pé, “Bí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti wà, ẹni tí èmi ń sìn, nítòótọ́ èmi yóò fi ara mi hàn fún Ahabu lónìí.”
15 E Elias disse: Como vive o SENHOR dos Exércitos, diante de quem me ponho de pé, certamente me mostrarei a ele hoje.
16 Bẹ́ẹ̀ ni Obadiah sì lọ láti pàdé Ahabu, ó sì sọ fún un, Ahabu sì lọ láti pàdé Elijah.
16 Assim, Obadias foi se encontrar com Acabe, e lhe contou; e Acabe foi se encontrar com Elias.
17 Nígbà tí Ahabu sì rí Elijah, ó sì wí fún un pé, “Ṣé ìwọ nìyìí, ìwọ tí ń yọ Israẹli lẹ́nu?”
17 E sucedeu, quando viu Elias, que Acabe disse a ele: És tu aquele que perturba Israel?
18 Elijah sì dá a lóhùn pé, “Èmi kò yọ Israẹli lẹ́nu, bí kò ṣe ìwọ àti ilé baba rẹ. Ẹ ti kọ òfin Olúwa sílẹ̀, ẹ sì ń tọ Baali lẹ́yìn.
18 E ele respondeu: Eu não tenho perturbado Israel; mas tu, e a casa do teu pai, ao abandonardes os mandamentos do SENHOR, e teres seguido a Baalim.
19 Nísinsin yìí kó gbogbo Israẹli jọ láti pàdé mi lórí òkè Karmeli. Àti kí o sì mú àádọ́ta lé ní irinwó (450) àwọn wòlíì Baali àti irinwó (400) àwọn wòlíì òrìṣà Aṣerah tí wọ́n ń jẹun ní tábìlì Jesebeli.”
19 Agora, portanto, mandai reunir a mim todo o Israel no monte Carmelo, e dos profetas de Baal, quatrocentos e cinquenta, e dos profetas dos bosques, quatrocentos, os quais comem à mesa de Jezabel.
20 Bẹ́ẹ̀ ni Ahabu ránṣẹ́ sí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ó sì kó àwọn wòlíì jọ sí orí òkè Karmeli.
20 Assim, Acabe enviou a todos os filhos de Israel e reuniu os profetas no Monte Carmelo.
21 Elijah sì lọ síwájú gbogbo àwọn ènìyàn, ó sì wí pé, “Yóò ti pẹ́ tó tí ẹ̀yin yóò máa ṣiyèméjì? Bí Olúwa bá ni Ọlọ́run, ẹ máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, ṣùgbọ́n bí Baali bá ni Ọlọ́run, ẹ máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.”
21 E Elias chegou diante de todo o povo, e disse: Por quanto tempo vos coxeareis entre duas opiniões? Se o SENHOR é Deus, segui-o; mas se o é Baal, então segui-o. E o povo não lhe respondeu com uma palavra sequer.
22 Nígbà náà ni Elijah wí fún wọn pé, “Èmi nìkan ṣoṣo ni ó kù ní wòlíì Olúwa, ṣùgbọ́n, àádọ́ta lé ní irinwó (450) ni wòlíì Baali.
22 Então, disse Elias ao povo: Eu, somente eu, permaneço um profeta do SENHOR; porém os profetas de Baal são quatrocentos e cinquenta homens.
23 Ẹ fún wa ní ẹgbọrọ akọ màlúù méjì. Jẹ́ kí wọn kí ó sì yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara wọn, kí wọn kí ó sì gé e sí wẹ́wẹ́, kí wọn kí ó sì tò ó sí orí igi, kí wọn kí ó má ṣe fi iná sí i. Èmi yóò sì tún ẹgbọrọ akọ màlúù kejì ṣe, èmi yóò sì tò ó sórí igi, èmi kì yóò sì fi iná sí i.
23 Que nos deem, portanto, dois novilhos; e que escolham um novilho para si, e o cortem em pedaços, e o disponham sobre lenha, e não coloquem fogo por baixo; e eu prepararei o outro novilho, e o disporei sobre lenha, e não colocarei fogo por baixo;
24 Nígbà náà ẹ ó sì ké pe orúkọ àwọn Ọlọ́run yín, èmi yóò sì ké pe orúkọ Olúwa. Ọlọ́run náà tí ó fi iná dáhùn, òun ni Ọlọ́run.”
24 e clamai vós o nome dos vossos deuses, e eu clamarei o nome do SENHOR; e o Deus que responder com fogo, que seja ele Deus. E todo o povo respondeu e disse: Está bem falado.
25 Elijah sì wí fún àwọn wòlíì Baali wí pé, “Ẹ yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara yín, kí ẹ sì tètè kọ́ ṣe é, nítorí ẹ̀yin pọ̀. Ẹ ké pe orúkọ àwọn ọlọ́run yín, ṣùgbọ́n ẹ má ṣe fi iná sí i.”
25 E Elias disse aos profetas de Baal: Escolhei um novilho para vós, e preparai-o primeiro; porquanto vós sois muitos; e clamai o nome dos vossos deuses, porém não coloquem fogo por baixo.
26 Nígbà náà ni wọ́n sì mú ẹgbọrọ akọ màlúù náà, tí a ti fi fún wọn, wọ́n sì ṣe é.
26 E eles tomaram o novilho que lhes fora dado, e o prepararam, e clamaram o nome de Baal desde a manhã até o meio-dia, dizendo: Ó Baal, ouve-nos. Todavia, não houve voz, nem ninguém que respondesse. E saltavam sobre o altar que fora feito.
27 Ní ọ̀sán gangan, Elijah bẹ̀rẹ̀ sí ń fi wọ́n ṣe ẹlẹ́yà ó sì wí pé, “Ẹ kígbe lóhùn rara Ọlọ́run sá à ni òun! Bóyá ó ń ṣe àṣàrò, tàbí kò ráyè, tàbí ó re àjò. Bóyá ó sùn, ó yẹ kí a jí i.”
27 E sucedeu, ao meio-dia, que Elias zombou deles, e disse: Gritai alto; porque ele é um deus; ou está conversando, ou ele está meditando, ou está em uma viagem, ou porventura dorme, e deve ser despertado.
28 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì kígbe lóhùn rara, wọ́n sì fi ọ̀bẹ àti ọ̀kọ̀ ya ara wọn gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn, títí tí ẹ̀jẹ̀ fi tú jáde ní ara wọn.
28 E eles gritaram alto, e se cortaram, segundo o seu costume, com facas e lancetas, até que o sangue se derramou sobre eles.
29 Nígbà tí ọjọ́ yẹ àtàrí, wọ́n sì ń fi òmùgọ̀ sọtẹ́lẹ̀ títí di àkókò ìrúbọ àṣálẹ́, ṣùgbọ́n kò sí ohùn, kò sì ṣí ìdáhùn, kò sì ṣí ẹni tí ó kà á sí.
29 E sucedeu, quando era passado o meio-dia, eles profetizaram até a hora da oferta do sacrifício do anoitecer, que não houve nem voz, nem ninguém para responder, tampouco alguém que se importasse.
30 Nígbà náà ni Elijah wí fún gbogbo àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ súnmọ́ mi.” Wọ́n sì súnmọ́ ọn, ó sì tún pẹpẹ Olúwa tí ó ti wó lulẹ̀ ṣe.
30 E Elias disse a todo o povo: Cheguem perto de mim. E todo o povo chegou perto dele. E ele consertou o altar do SENHOR que estava quebrado.
31 Elijah sì mú òkúta méjìlá, ọ̀kọ̀ọ̀kan fún ẹ̀yà ọmọ Jakọbu kan, ẹni tí ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ wá wí pé, “Israẹli ni orúkọ rẹ̀ yóò máa jẹ́.”
31 E Elias pegou doze pedras, segundo o número das tribos dos filhos de Jacó, a quem a palavra do SENHOR veio, dizendo: Israel será o teu nome;
32 Ó sì tẹ́ pẹpẹ pẹ̀lú àwọn òkúta wọ̀nyí ní orúkọ Olúwa, ó sì wa yàrá yí pẹpẹ náà ká, tí ó lè gba ìwọ̀n òsùwọ̀n irúgbìn méjì.
32 e com as pedras ele edificou um altar no nome do SENHOR; e fez uma trincheira ao redor do altar, grande o suficiente para conter duas medidas de semente.
33 Ó sì to igi náà dáradára, ó sì ké ẹgbọrọ akọ màlúù náà wẹ́wẹ́, ó sì tò ó sórí igi. Nígbà náà ni ó sì wí fún wọn wí pé, “Ẹ fi omi kún ìkòkò mẹ́rin, kí ẹ sì tu sórí ẹbọ sísun àti sórí igi náà.”
33 E ele colocou a lenha em ordem, e cortou o novilho em pedaços, e o colocou sobre a lenha, e disse: Enchei quatro barricas de água, e derramai-a em cima do sacrifício queimado, e sobre a lenha.
34 Ó sì wí pe, “Ẹ ṣe é ní ìgbà kejì.” Wọ́n sì ṣe é ní ìgbà kejì.
34 E ele disse: Fazei-o pela segunda vez. E eles o fizeram pela segunda vez. E ele disse: Fazei-o pela terceira vez. E eles o fizeram pela terceira vez.
35 Omi náà sì sàn yí pẹpẹ náà ká, ó sì fi omi kún yàrá náà pẹ̀lú.
35 E a água escorreu ao redor do altar; e ele também encheu a trincheira de água.
36 Ó sì ṣe, ní ìrúbọ àṣálẹ́, wòlíì Elijah sì súnmọ́ tòsí, ó sì gbàdúrà wí pé, “Olúwa, Ọlọ́run Abrahamu, Isaaki àti Israẹli, jẹ́ kí ó di mí mọ̀ lónìí pé ìwọ ni Ọlọ́run ní Israẹli àti pé èmi ni ìránṣẹ́ rẹ, àti pé mo ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí nípa àṣẹ rẹ.
36 E sucedeu, na hora da oferta do sacrifício da tarde, que Elias, o profeta, aproximou-se e disse: SENHOR Deus de Abraão, Isaque e de Israel, que seja conhecido neste dia que tu és Deus em Israel, e que eu sou teu servo, e que tenho feito todas estas coisas mediante a tua palavra.
37 Gbọ́ ti èmi, Olúwa, gbọ́ ti èmi, kí àwọn ènìyàn wọ̀nyí lè mọ̀ pé ìwọ Olúwa ni Ọlọ́run àti pé ìwọ tún yí ọkàn wọn padà.”
37 Ouve-me, ó SENHOR, ouve-me, para que este povo possa saber que tu és o SENHOR Deus, e que tu tens feito se volver novamente o seu coração.
38 Nígbà náà ni iná Olúwa bọ́ sílẹ̀, ó sì sun ẹbọ sísun náà àti igi, àti àwọn òkúta, àti erùpẹ̀, ó sì tún lá omi tí ń bẹ nínú yàrá náà.
38 Então, o fogo do SENHOR caiu, e consumiu o sacrifício queimado, e a lenha, e as pedras, e o pó, e ainda lambeu a água que estava na trincheira.
39 Nígbà tí gbogbo àwọn ènìyàn sì rí èyí, wọ́n da ojú wọn bolẹ̀, wọ́n sì kígbe pé, “Olúwa, òun ni Ọlọ́run! Olúwa, òun ni Ọlọ́run!”
39 E, quando todo o povo viu isto, eles caíram sobre as suas faces, e disseram: O SENHOR, ele é o Deus; o SENHOR, ele é o Deus.
40 Nígbà náà ni Elijah sì pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ mú àwọn wòlíì Baali. Ẹ má ṣe jẹ́ kí ọ̀kan nínú wọn kí ó sálọ!” Wọ́n sì mú wọn, Elijah sì mú wọn sọ̀kalẹ̀ sí àfonífojì Kiṣoni, ó sì pa wọ́n níbẹ̀.
40 E Elias lhes disse: Tomai os profetas de Baal; não deixem escapar nenhum deles. E eles os pegaram; e Elias os fez descer até o ribeiro de Quisom, e ali os matou.
41 Elijah sì wí fún Ahabu pé, “Lọ, jẹ, kí o sì mu, nítorí ìró ọ̀pọ̀lọpọ̀ òjò ń bọ̀.”
41 E Elias disse a Acabe: Levanta-te, come e bebe; porque há som de abundante chuva.
42 Bẹ́ẹ̀ ni Ahabu gòkè lọ láti jẹ àti láti mu. Ṣùgbọ́n Elijah gun orí òkè Karmeli lọ ó sì tẹríba, ó sì fi ojú rẹ̀ sí agbede-méjì eékún rẹ̀.
42 Assim, Acabe subiu para comer e beber. E Elias subiu até o cume do Carmelo; e se lançou sobre a terra, e pôs a face entre os joelhos,
43 Ó sì wí fún ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé, “Lọ, kí o sì wo ìhà Òkun, òun sì gòkè lọ, ó sì wò.”
43 e disse ao seu servo: Sobe agora, olha em direção ao mar. E ele subiu, e olhou, e disse: Não há nada. E ele disse: Vai novamente, sete vezes.
44 Nígbà keje, ìránṣẹ́ náà sì wí pé, “Àwọsánmọ̀ kékeré kan dìde láti inú Òkun, gẹ́gẹ́ bí ọwọ́ ènìyàn.”
44 E sucedeu, na sétima vez, que ele disse: Eis que lá se levante uma pequena nuvem do mar, semelhante a mão de homem. E ele disse: Sobe, e dize a Acabe: Prepara a tua carruagem, e desce, para que a chuva não te pare.
45 Ó sì ṣe, nígbà díẹ̀ sí i, ọ̀run sì ṣú fún àwọsánmọ̀, ìjì sì dìde, òjò púpọ̀ sì rọ̀, Ahabu sì gun kẹ̀kẹ́ lọ sí Jesreeli.
45 E sucedeu, entretanto, que o céu ficou negro com nuvens e vento, e houve uma grande chuva. E Acabe montou, e foi até Jezreel.
46 Agbára Olúwa sì ń bẹ lára Elijah; ó sì di àmùrè ẹ̀gbẹ́ rẹ, ó sì sáré níwájú Ahabu títí dé Jesreeli.
46 E a mão do SENHOR esteve sobre Elias; e ele cingiu os seus lombos, e correu adiante de Acabe até a entrada de Jezreel.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Reis 18, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.