1 Crônicas 7
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NAA
1 Àwọn ọmọ Isakari:
1 Os filhos de Issacar foram: Tola, Puá, Jasube e Sinrom, quatro ao todo.
2 Àwọn ọmọ Tola:
2 Os filhos de Tola foram: Uzi, Refaías, Jeriel, Jamai, Ibsão e Samuel, chefes das suas famílias, descendentes de Tola; homens valentes nas suas gerações, cujo número, nos dias de Davi, foi de vinte e dois mil e setecentos.
3 Àwọn ọmọ, Ussi:
3 O filho de Uzi foi Izraías; e os filhos de Izraías foram: Micael, Obadias, Joel e Issias, cinco ao todo; todos eles chefes.
4 Gẹ́gẹ́ bí ìtàn ìdílé wọn láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n ní ọkùnrin ẹgbàá mẹ́rìndínlógójì (36,000) tí ó ti ṣe tan fún ogun, nítorí wọ́n ní ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ àti ìyàwó.
4 Tinham, nas suas gerações, segundo as suas famílias, em tropas de guerra, trinta e seis mil homens; pois tinham muitas mulheres e filhos.
5 Àwọn ìbátan tí ó jẹ́ alágbára akọni àwọn ọkùnrin tí ó jẹ́ ti àwọn ìdílé Isakari, bí a ti tò ó lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́tàdínláàádọ́rin (87,000) ni gbogbo rẹ̀.
5 Seus irmãos, em todas as famílias de Issacar, homens valentes, foram oitenta e sete mil, todos registrados pelas suas genealogias.
6 Àwọn ọmọ mẹ́ta Benjamini:
6 Os filhos de Benjamim foram: Belá, Bequer e Jediael, três ao todo.
7 Àwọn ọmọ Bela:
7 Os filhos de Belá foram: Esbom, Uzi, Uziel, Jerimote e Iri; cinco ao todo; chefes das suas famílias, homens valentes, foram vinte e dois mil e trinta e quatro, registrados pelas suas genealogias.
8 Àwọn ọmọ Bekeri:
8 Os filhos de Bequer foram: Zemira, Joás, Eliézer, Elioenai, Onri, Jerimote, Abias, Anatote e Alemete; todos filhos de Bequer.
9 Ìtàn ìdílé wọn láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn tí a kọ lẹ́sẹẹsẹ jẹ́ ti àwọn olórí ìdílé àti ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà ogún ó lé nígba (20,200) ọkùnrin alágbára.
9 O número deles, registrados pelas suas genealogias, segundo as suas gerações, chefes das suas famílias, homens valentes, vinte mil e duzentos.
10 Ọmọ Jediaeli:
10 O filho de Jediael foi Bilã; os filhos de Bilã foram: Jeús, Benjamim, Eúde, Quenaana, Zetã, Társis e Aisaar.
11 Gbogbo àwọn ọmọ Jediaeli jẹ́ olórí. Àwọn ẹgbẹ̀rún mẹ́tàdínlógún ó lé nígba (17,200) akọni ọkùnrin ni ó ti ṣetán láti jáde lọ sí ogun.
11 Todos estes, filhos de Jediael, foram chefes das suas famílias, homens valentes, dezessete mil e duzentos, capazes de sair à guerra.
12 Àti Ṣuppimu, àti Huppimu, àwọn ọmọ Iri, àti Huṣimu, àwọn ọmọ Aheri.
12 Supim e Hupim eram filhos de Ir; e Husim era filho de Aer.
13 Àwọn ọmọ Naftali:
13 Os filhos de Naftali foram: Jaziel, Guni, Jezer e Salum, filhos de Bila.
14 Àwọn ìran ọmọ Manase:
14 Os filhos de Manassés foram: Asriel, de sua concubina síria, que também deu à luz Maquir, pai de Gileade.
15 Makiri sì mú ìyàwó láti àárín àwọn ará Huppimu àti Ṣuppimu. Orúkọ arábìnrin rẹ̀ a máa jẹ́ Maaka. Orúkọ ìran ọmọ mìíràn a máa jẹ́ Selofehadi, tí ó ní àwọn ọmọbìnrin nìkan ṣoṣo.
15 Maquir tomou a irmã de Hupim e Supim por mulher. O nome dela era Maaca; o nome do irmão de Maquir era Zelofeade, o qual teve só filhas.
16 Maaka, ìyàwó Makiri bí ọmọkùnrin kan. Ó sì sọ orúkọ rẹ̀ ní Peresi. Ó sì pe arákùnrin rẹ̀ ní Ṣereṣi, àwọn ọmọ rẹ̀ sì ní Ulamu àti Rakemu.
16 Maaca, mulher de Maquir, teve um filho, a quem chamou Perez; irmão deste foi Seres. Os filhos de Perez foram Ulão e Requém.
17 Ọmọ Ulamu:
17 O filho de Ulão foi Bedã. Tais foram os filhos de Gileade, filho de Maquir, filho de Manassés.
18 Arábìnrin rẹ̀. Hamoleketi bí Iṣhodi, Abieseri àti Mahila.
18 Sua irmã Hamolequete deu à luz Isode, Abiezer e Macla.
19 Àwọn ọmọ Ṣemida sì jẹ́:
19 Os filhos de Semida foram: Aiã, Siquém, Liqui e Anião.
20 Àwọn ìran ọmọ Efraimu:
20 O filho de Efraim foi Sutela, de quem foi filho Berede, de quem foi filho Taate, de quem foi filho Eleada, de quem foi filho Taate,
21 Sabadi ọmọ, rẹ̀,
21 de quem foi filho Zabade, de quem foi filho Sutela; e ainda Ézer e Eleade, mortos pelos homens de Gate, naturais da terra, pois eles foram roubar o gado destes.
22 Efraimu baba wọn ṣọ̀fọ̀ fún wọn ní ọjọ́ púpọ̀, àwọn ìbátan rẹ̀ wá láti tù ú nínú.
22 Efraim, seu pai, chorou por eles muitos dias, e os irmãos dele foram consolá-lo.
23 Nígbà náà, ó sùn pẹ̀lú, ìyàwó rẹ̀, ó sì lóyún ó sì bí ọmọkùnrin kan. Ó sì sọ ọ́ ní Beriah nítorí òfò ti wà nínú ìdílé náà.
23 Depois, teve relações com sua mulher, ela ficou grávida e teve um filho, a quem ele chamou Berias, por causa da desgraça que sua família havia sofrido.
24 Ọmọbìnrin rẹ̀ sì jẹ́ Ṣerah, ẹni tí ó kọ́ ìsàlẹ̀ àti òkè Beti-Horoni àti Useni-Ṣerah pẹ̀lú.
24 Sua filha foi Seerá, que edificou Bete-Horom-de-Baixo e Bete-Horom-de-Cima, bem como Uzém-Seerá.
25 Refa jẹ́ ọmọ rẹ̀, Resefi ọmọ rẹ̀,
25 O filho de Berias foi Refa, de quem foi filho Resefe, de quem foi filho Tela, de quem foi filho Taã,
26 Laadani ọmọ rẹ̀ Ammihudu ọmọ rẹ̀,
26 de quem foi filho Ladã, de quem foi filho Amiúde, de quem foi filho Elisama,
27 Nuni ọmọ rẹ̀
27 de quem foi filho Num, de quem foi filho Josué.
28 Ilẹ̀ wọn àti ìfìdíkalẹ̀ wọn ni Beteli àti àwọn ìletò tí ó yíká, Narani lọ sí ìhà ìlà-oòrùn, Geseri àti àwọn ìletò rẹ̀ lọ sí ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Ṣekemu àti àwọn ìletò rẹ̀ ní ọ̀nà lọ sí Ayahi àti àwọn ìletò.
28 A propriedade e habitação deles foram: Betel e as suas aldeias; ao leste, Naarã; e, a oeste, Gezer e as suas aldeias, Siquém e as suas aldeias, até Aia e as suas aldeias;
29 Lẹ́gbẹ̀ ìpínlẹ̀ ti Manase ni Beti-Ṣeani, Taanaki, Megido àti Dori lápapọ̀ pẹ̀lú àwọn ìletò rẹ̀. Àwọn ìran ọmọ Josẹfu ọmọ Israẹli ń gbé nínú ìlú wọ̀nyí.
29 do lado dos filhos de Manassés, Bete-Seã e as suas aldeias, Taanaque e as suas aldeias, Megido e as suas aldeias, Dor e as suas aldeias; nestas, habitaram os filhos de José, filho de Israel.
30 Àwọn ọmọ Aṣeri:
30 Os filhos de Aser foram: Imna, Isvá, Isvi e Berias e Sera, irmã deles.
31 Àwọn ọmọ Beriah:
31 Os filhos de Berias foram: Héber e Malquiel; este foi o pai de Birzavite.
32 Heberi jẹ́ baba Jafileti, Ṣomeri àti Hotami àti ti arábìnrin wọn Ṣua.
32 Héber gerou Jaflete, Somer, Hotão e Suá, irmã deles.
33 Àwọn ọmọ Jafileti:
33 Os filhos de Jaflete foram: Pasaque, Bimal e Asvate; estes foram os filhos de Jaflete.
34 Àwọn ọmọ Ṣomeri:
34 Os filhos de Semer foram: Aí, Roga, Jeubá e Arã.
35 Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Helemu
35 Os filhos de seu irmão Helém foram: Zofa, Imna, Seles e Amal.
36 Àwọn ọmọ Sofahi:
36 Os filhos de Zofa foram: Sua, Harnefer, Sual, Beri, Inra,
37 Beseri, Hodi, Ṣamma, Ṣilisa, Itrani àti Bera.
37 Bezer, Hode, Sama, Silsa, Itrã e Beera.
38 Àwọn ọmọ Jeteri:
38 Os filhos de Jéter foram: Jefoné, Pispa e Ara.
39 Àwọn ọmọ Ulla:
39 Os filhos de Ula foram: Ara, Haniel e Rizia.
40 Gbogbo wọ̀nyí jẹ́ ìran ọmọ Aṣeri—olórí ìdílé, àṣàyàn ọkùnrin, alágbára jagunjagun àti olórí nínú àwọn ìjòyè. Iye àwọn tí a kà yẹ fún ogun, gẹ́gẹ́ bí à ti ṣe kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé wọn jẹ́ ẹgbàá mẹ́tàlá (26,000) ọkùnrin.
40 Todos estes foram filhos de Aser, chefes das famílias, escolhidos, homens valentes, chefes de príncipes, registrados nas suas genealogias para o serviço na guerra; seu número foi de vinte e seis mil homens.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 7, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.