1 Crônicas 29
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Nígbà náà, ọba Dafidi sọ fún gbogbo àpéjọ pé, “Ọmọ mi Solomoni, èyí tí Ọlọ́run ti yàn, sì kéré ó sì jẹ́ aláìmòye. Iṣẹ́ náà tóbi, nítorí ìkọ́lé bí ti ààfin kì í ṣe fún ènìyàn ṣùgbọ́n fún Olúwa Ọlọ́run.
1 Sobretudo, o rei Davi, disse a toda a congregação: Salomão, meu filho, a quem somente Deus tem escolhido, é ainda jovem e tenro, e a obra é grande; porque o palácio não é para homem, mas para o SENHOR Deus.
2 Pẹ̀lú gbogbo ìrànlọ́wọ́ mi èmi ti pèsè fún ilé Ọlọ́run mi wúrà fún iṣẹ́ wúrà, fàdákà fún ti fàdákà, idẹ fún ti idẹ, irin fún ti irin àti igi fún ti igi àti òkúta oníyebíye fún títọ́ rẹ̀, òkúta lóríṣìíríṣìí, àwọ̀ àti oríṣìíríṣìí ẹ̀yà òkúta àti òkúta dáradára kan gbogbo wọ̀nyí ní iye púpọ̀.
2 Agora, tenho preparado, com toda a minha força, para a casa do meu Deus, o ouro para as coisas a serem feitas de ouro, e a prata para as coisas de prata, e o bronze para as coisas de bronze, o ferro para as coisas de ferro, e a madeira para as coisas de madeira; pedras de ônix, e pedras para serem assentadas, pedras cintilantes, e de diversas cores, e toda sorte de pedras preciosas, e pedras de mármore em abundância.
3 Yàtọ̀ fún èyí, nínú ìfọkànsìn mi sí ilé Ọlọ́run mi, èmí fi ìṣúra mi tìkára mi ti wúrà àti fàdákà fún ilé Ọlọ́run mi. Jù gbogbo rẹ̀ lọ, èmi ti pèsè fún ilé mímọ́ ti Olúwa yìí,
3 Além disso, em meu amor pela casa do meu Deus, os meus próprios bens, de ouro e prata os tenho dado à casa do meu Deus, acima e além de tudo o que tenho provido para a casa do santuário,
4 ẹgbẹ̀rún mẹ́ta (3,000) tálẹ́ǹtì wúrà, ti wúrà Ofiri àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin (7,000) tálẹ́ǹtì fàdákà dídára, fún bíbo àwọn ògiri ilé náà.
4 a saber, três mil talentos de ouro, do ouro de Ofir, e sete mil talentos de prata refinada, para revestir, as paredes das casas;
5 Fún iṣẹ́ wúrà àti fàdákà náà, àti fún oríṣìí iṣẹ́ ti ó yẹ ní ṣíṣe nípasẹ̀ àwọn tí ó ní òye oríṣìíríṣìí iṣẹ́. Nísinsin yìí, ta ni ó ní ìfẹ́ sí yíya ará rẹ̀ sọ́tọ̀ lónìí sí Olúwa?”
5 o ouro para as coisas de ouro, e a prata para coisas de prata e para toda sorte de obra a ser feita pelas mãos de artesãos. E neste dia quem, está disposto a consagrar o seu serviço ao SENHOR?
6 Nígbà náà àwọn aṣáájú àwọn ìdílé, àwọn ìjòyè àwọn ẹ̀yà Israẹli, àwọn alákòóso ẹgbẹgbẹ̀wàá àti alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún àti àwọn oníṣẹ́ tí ó wà ní ìdí iṣẹ́ ọba ní ìfẹ́ sí i.
6 Então, o chefe dos pais e príncipes das tribos de Israel, e os capitães de milhares e de centúrias, com os governantes da obra do rei, contribuíram voluntariamente,
7 Wọ́n fi sílẹ̀ fún iṣẹ́ lórí ilé Ọlọ́run, ẹgbẹ̀rún márùn-ún (5,000) tálẹ́ǹtì àti ẹgbẹ̀rin mẹ́wàá (10,000) wúrà, ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá (10,000) tálẹ́ǹtì fàdákà, ẹgbàá mẹ́sàn (18,000) tálẹ́ǹtì idẹ àti ọgọ́rin ẹgbẹ̀rin (100,000) tálẹ́ǹtì irin.
7 e deram para o serviço da casa de Deus: de ouro, cinco mil talentos e dez mil dracmas; de prata, dez mil talentos; de bronze, dezoito mil talentos, e cem mil talentos de ferro.
8 Ẹnikẹ́ni tí ó ní òkúta iyebíye fi wọn sí ilé ìṣúra ilé Olúwa ní abẹ́ ìtọ́jú Jehieli ará Gerṣoni.
8 E aqueles que possuíam pedras preciosas deram-nas ao tesouro da casa do SENHOR, pela mão de Jeiel, o gersonita.
9 Àwọn ènìyàn láyọ̀ nínú ìṣesí àtọkànwá fi sílẹ̀ àwọn olórí wọn, nítorí tí wọ́n ti fi sílẹ̀ ní ọ̀fẹ́ pẹ̀lú gbogbo ọkàn sí Olúwa. Dafidi ọba pẹ̀lú yọ̀ gidigidi.
9 Então, o povo se regozijou, por aquilo que eles ofereceram voluntariamente, porque com coração perfeito ofereceram voluntariamente ao SENHOR; e o rei Davi, também se regozijou com grande alegria.
10 Dafidi yin Olúwa níwájú gbogbo àwọn tí ó péjọ, wí pé,
10 Pelo que Davi bendisse ao SENHOR diante de toda a congregação; e Davi disse: Bendito sejas tu, SENHOR Deus de Israel, nosso pai, para todo o sempre.
11 Tìrẹ Olúwa ni títóbi àti agbára pẹ̀lú ìyìn
11 Tua, ó SENHOR, é a grandeza, e o poder, e a glória, e a vitória, e a majestade; porque tudo o que está no céu e na terra é teu; teu é o reino, ó SENHOR, e tu és exaltado como cabeça acima de tudo.
12 Ọlá àti ọ̀wọ̀ wá láti ọ̀dọ̀ Rẹ;
12 Tanto as riquezas, como a honra vem de ti, e tu reinas sobre tudo; e na tua mão está o poder e a força; e na tua mão está o engrandecer, e o dar poder a todos.
13 Nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, àwa fi ọpẹ́ fún Ọ,
13 Agora, pois, nosso Deus, damos graças a ti, e louvamos o teu glorioso nome.
14 “Ṣùgbọ́n ta ni èmi, àti ta ni àwọn ènìyàn mi, tí a fi lè ṣe ìrànlọ́wọ́ tinútinú bí irú èyí? Gbogbo nǹkan wá láti ọ̀dọ̀ rẹ ní ti wá, àwa sì ti fífún ọ láti ara ohun tí ó wá láti ọwọ́ rẹ.
14 Porém, quem sou eu, e quem é o meu povo, para que sejamos capazes de oferecer, tão voluntariamente, desta maneira? Porque todas as coisas vêm de ti, e do que é teu temos dado a ti.
15 Àwa jẹ́ àjèjì àti àlejò ní ojú rẹ gẹ́gẹ́ bí baba ńlá a wa, àwọn ọjọ́ wa lórí ilẹ̀ ayé rí bí òjìji láìsí ìrètí.
15 Porque somos estrangeiros e peregrinos diante de ti, como foram todos os nossos pais; os nossos dias na terra são como uma sombra, e não há nenhuma esperança.
16 Olúwa Ọlọ́run wa tí fi gbogbo púpọ̀ yìí tí àwa ti pèsè fún kíkọ́ ilé Olúwa fun orúkọ, mímọ́ rẹ̀, ó wá láti ọwọ́ ọ̀ rẹ, gbogbo rẹ̀ sì jẹ́ tirẹ̀.
16 Ó SENHOR, nosso Deus, toda esta abundância que temos preparado para te edificar uma casa para o teu santo nome vem da tua mão, e é toda tua.
17 Èmi mọ̀ Ọlọ́run mi, wí pé ìwọ̀ dán ọkàn wò, ó sì tẹ́ ọ lọ́rùn pẹ̀lú òtítọ́ inú. Gbogbo nǹkan wọ̀nyí ni èmi ti fi sílẹ̀ pẹ̀lú tìfẹ́tìfẹ́ pẹ̀lú òtítọ́. Nísinsin yìí èmi ti rí i pẹ̀lú ayọ̀ bí àwọn ènìyàn yìí tí ó wà níbí ti fi fún ọ pẹ̀lú tìfẹ́tìfẹ́.
17 Sei também, meu Deus, que tu provas o coração, e tens prazer na retidão. Quanto a mim, na retidão do meu coração tenho oferecido voluntariamente todas estas coisas; e agora vi com alegria o teu povo, o qual está presente aqui, oferecer voluntariamente a ti.
18 Olúwa Ọlọ́run àwọn baba a wa Abrahamu, Isaaki àti Israẹli pa ìfẹ́ yìí mọ́ nínú ọkàn àwọn ènìyàn rẹ títí láé pẹ̀lú pípa ọkàn mọ́ lóòtítọ́ sí ọ.
18 Ó SENHOR Deus de Abraão, Isaque, e de Israel, nossos pais, conserva para sempre na imaginação dos pensamentos do coração do teu povo, e prepara o seu coração para ti;
19 Àti fún ọmọ mi Solomoni ní ìfọkànsìn tòótọ́ láti pa àṣẹ rẹ mọ́ àwọn ohun tí ó nílò àti òfin àti láti ṣe ohun gbogbo láti kọ́ ààfin bí ti ọba fún èyí tí mo ti pèsè.”
19 e dá a Salomão, meu filho, um coração perfeito, para guardar os teus mandamentos, os teus testemunhos, e os teus estatutos, e para fazer todas estas coisas, e para edificar o palácio, para o qual tenho feito provisão.
20 Dafidi sì sọ fún gbogbo ìjọ ènìyàn pé, “Nísinsin yìí, ẹ fi ìyìn fún Olúwa Ọlọ́run yín.” Gbogbo ènìyàn sì fi ìyìn fún Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn, wọ́n sì tẹ orí wọn ba, wọ́n wólẹ̀ fún Olúwa àti ọba.
20 E Davi disse a toda a congregação: Agora, bendizei ao SENHOR vosso Deus. E toda a congregação bendisse ao SENHOR Deus de seus pais, e inclinaram suas cabeças, e se prostraram ao SENHOR, e ao rei.
21 Ni ọjọ́ kejì, wọ́n rú ẹbọ sí Olúwa, wọ́n sì rú ẹbọ sísun sí i: ẹgbẹ̀rún (1,000) kan akọ màlúù, ẹgbẹ̀rin (1,000) kan àgbò, àti ẹgbẹ̀rin kan akọ ọ̀dọ́-àgùntàn. Lápapọ̀ pẹ̀lú ọrẹ mímu àti àwọn ẹbọ mìíràn ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ fún gbogbo Israẹli.
21 E eles imolaram sacrifícios ao SENHOR, e ofereceram ofertas queimadas ao SENHOR, no amanhecer posterior àquele dia, a saber, mil novilhos, mil carneiros, e mil cordeiros, com as suas ofertas de bebida, e sacrifícios em abundância por todo o Israel;
22 Wọ́n jẹ wọ́n sì mu pẹ̀lú ayọ̀ kíkún ní iwájú Olúwa ní ọjọ́ náà.
22 e comeram e beberam diante do SENHOR naquele dia com grande júbilo. E fizeram Salomão, o filho de Davi, rei pela segunda vez, e o ungiram para o SENHOR para ser o governador-mor, e Zadoque para ser sacerdote.
23 Bẹ́ẹ̀ ni Solomoni jókòó lórí ìtẹ́ Olúwa gẹ́gẹ́ bí ọba ní ipò baba a rẹ̀ Dafidi. O ṣe àṣeyọrí, gbogbo Israẹli sì gbọ́rọ̀ sí i lẹ́nu.
23 Então, Salomão assentou-se no trono do SENHOR como rei em lugar de Davi, seu pai, e prosperou; e todo o Israel lhe obedeceu.
24 Gbogbo àwọn ìjòyè àti àwọn ọkùnrin alágbára, pẹ̀lú gbogbo àwọn ọmọ ọba Dafidi tẹrí ara wọn ba fún ọba Solomoni.
24 E todos os príncipes, e os homens poderosos, e, de modo semelhante, todos os filhos de Davi, submeteram-se ao rei Salomão.
25 Olúwa gbé Solomoni ga púpọ̀ ní ojú gbogbo Israẹli, ó sì kẹ́ ẹ ní ìkẹ́ ọláńlá, ní irú èyí tí a kò kẹ́ ọba kankan ṣáájú rẹ̀ tí ó jẹ lórí Israẹli.
25 E o SENHOR magnificou Salomão sobejamente à vista de todo o Israel, e outorgou a ele tamanha majestade real, como não havia se concedido em Israel a nenhum rei antes dele.
26 Dafidi ọmọ Jese jẹ́ ọba lórí gbogbo Israẹli.
26 Assim, Davi, o filho de Jessé, reinou sobre todo o Israel.
27 Ó jẹ ọba lórí Israẹli fún ogójì ọdún; ọdún méje ni ó jẹ ọba ní Hebroni, ó sì jẹ ọba ní ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ní Jerusalẹmu.
27 E o tempo que ele reinou sobre Israel foi de quarenta anos; sete anos ele reinou em Hebrom, e trinta e três anos ele reinou em Jerusalém.
28 Òun sì darúgbó, ó sì kú ikú rere, ó gbádùn ẹ̀mí gígùn, ọlá àti ọrọ̀. Solomoni ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
28 E ele morreu em boa velhice, cheio de dias, riquezas, e honra; e Salomão, seu filho, reinou em seu lugar.
29 Ní ti ohun tí ó ṣẹlẹ̀ nígbà ìjọba ọba Dafidi, láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin, a kọ wọ́n sínú ìwé ìrántí ti Samuẹli aríran, ìwé ìrántí ti Natani wòlíì àti ìwé ìrántí ti Gadi aríran,
29 Ora, os atos do rei Davi, os primeiros e os últimos, eis que estão escritos no livro de Samuel, o vidente, e no livro de Natã, o profeta; e no livro de Gade, o vidente;
30 lápapọ̀, pẹ̀lú gbogbo ìjọba àti agbára rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ìgbà tí ó kọjá lórí rẹ̀, àti lórí Israẹli, àti lórí gbogbo àwọn ìjọba gbogbo ilẹ̀ náà.
30 com todo o seu reinado e poder, e os tempos que sobrevieram a ele, e a Israel, e a todos os reinos das terras.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 29, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.