1 Crônicas 27

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ

Sair da comparação
1 Wọ̀nyí ni ìwé àkójọ orúkọ àwọn ọmọ Israẹli, àwọn olórí àwọn ìdílé, àwọn balógun ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn balógun ọ̀rọ̀ọ̀rún àti àwọn ìjòyè wọn. Tí ó n sin ọba nínú gbogbo ohun tí ó kan ìpín àwọn ọmọ-ogun tí ó wà lẹ́nu iṣẹ́ ìsìn ní oṣooṣù ní gbogbo ọdún. Ìpín kọ̀ọ̀kan jẹ́ ẹgbàá méjìlá (24,000) ọkùnrin.
1 Ora, os filhos de Israel segundo o seu número, a saber, os pais chefes e capitães de milhares e centúrias, e os seus oficiais que serviam ao rei em qualquer negócio das turmas que entravam e saíam cada mês durante todos os meses do ano, eram em cada turma vinte e quatro mil.
2 Ní ti alákòóso lórí ìpín kìn-ín-ní fún oṣù kìn-ín-ní jẹ́ Jaṣobeamu ọmọ Sabdieli àwọn ọkùnrin ẹgbàá méjìlá (24,000) ní ó wà ní abẹ́ ìpín tirẹ̀.
2 Sobre a primeira turma do primeiro mês estava Jasobeão, o filho de Zabdiel; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
3 Ó jẹ́ ìran ọmọ Peresi àti olóyè fún gbogbo àwọn ìjòyè ológun fún oṣù kìn-ín-ní.
3 Ele era dos filhos de Perez o chefe de todos os capitães do exército do primeiro mês.
4 Alákòóso fún ìpín àwọn ọmọ-ogun fún oṣù kejì jẹ́ Dodai ará Ahohi; Mikloti jẹ́ olórí ìpín tirẹ̀. Ọkùnrin ẹgbàá méjìlá (24,000) ni ó wà ní ìpín tirẹ̀.
4 E sobre a turma do segundo mês estava Dodai, um aoíta, e da sua turma era também Miclote, o governante; na sua turma, de modo semelhante, eram vinte e quatro mil.
5 Olórí àwọn ọmọ-ogun ẹlẹ́ẹ̀kẹta fún oṣù kẹta jẹ́ Benaiah ọmọ Jehoiada àlùfáà. Ó jẹ́ olóyè, àwọn ọkùnrin ẹgbàá méjìlá (24,000) ní ó wà ní ìpín tirẹ̀.
5 O terceiro capitão do exército no terceiro mês foi Benaia, o filho de Joiada, um sumo sacerdote; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
6 Èyí ni Benaiah náà tí ó jẹ́ ọkùnrin ńlá láàrín àwọn ọgbọ̀n àti lórí àwọn ọgbọ̀n. Ọmọ rẹ̀ Amisabadi jẹ́ alákòóso lórí ìpín tirẹ̀.
6 Este é aquele Benaia, que era forte entre os trinta, e acima dos trinta; e na sua turma estava Amizabade, seu filho.
7 Ẹlẹ́ẹ̀kẹrin fún oṣù kẹrin, jẹ́ Asaheli arákùnrin Joabu: ọmọ rẹ̀ Sebadiah jẹ́ arọ́pò rẹ̀. Ẹgbàá méjìlá (24,000) ọkùnrin ni ó wà ní ìpín rẹ̀.
7 O quarto capitão do quarto mês foi Asael, o irmão de Joabe, e depois dele Zebadias, seu filho; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
8 Ẹ̀karùnún fún oṣù karùn-ún, jẹ́ olórí Ṣamhuti ará Israhi. Ẹgbàá méjìlá (24,000) ọkùnrin ní ó wà ní ìpín tirẹ̀.
8 O quinto capitão do quinto mês era Samute, o Izraíta; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
9 Ẹ̀kẹfà fún oṣù kẹfà jẹ́ Ira ọmọ Ikẹsi, ará Tekoi. Ọkùnrin ẹgbàá méjìlá (24,000) ni ó wà ní ìpín rẹ̀.
9 O sexto capitão do sexto mês foi Ira, o filho de Iques, o tecoíta; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
10 Èkeje fún oṣù keje jẹ́ Helesi ará Peloni, ará Efraimu. Ọkùnrin ẹgbàá méjìlá (24,000) ni o wà ní ìpín rẹ̀.
10 O sétimo capitão do sétimo mês foi Heles, o pelonita, dos filhos de Efraim; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
11 Ẹ̀kẹjọ fún oṣù kẹjọ jẹ́ Sibekai ará Huṣati, ará Sera ọkùnrin ẹgbàá méjìlá (24,000) ni ó wà ní ìpín rẹ̀.
11 O oitavo capitão do oitavo mês foi Sibecai, o husatita, dos zeraítas; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
12 Ẹ̀kẹsànán fún oṣù kẹsànán jẹ́. Abieseri ará Anatoti, ará Benjamini ọkùnrin ẹgbàá méjìlá (24,000) ni ó wà ní ìpín rẹ̀.
12 O nono capitão do nono mês foi Abiezer, o anatotita, dos benjamitas; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
13 Ẹ̀kẹwàá fún oṣù kẹwàá jẹ́ Maharai ará Netofa, ará Sera ọkùnrin ẹgbàá méjìlá (24,000) ni ó wà ní ìpín rẹ̀.
13 O décimo capitão do décimo mês foi Maarai, o netofatita, dos zeraítas; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
14 Ìkọkànlá fún oṣù kọkànlá jẹ́ Benaiah ará Piratoni ará Efraimu ọkùnrin ẹgbàá méjìlá (24,000) ni ó wà ní ìpín tirẹ̀.
14 O undécimo capitão do undécimo mês foi Benaia, o piratonita, dos filhos de Efraim; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
15 Èkejìlá fún oṣù kejìlá jẹ́ Heldai ará Netofa láti ìdílé Otnieli. Ẹgbàá méjìlá (24,000) ọkùnrin ni ó wà ní ìpín tirẹ̀.
15 O duodécimo capitão do duodécimo mês foi Heldai, o netofatita, de Otniel; e na sua turma estavam vinte e quatro mil.
16 Àwọn ìjòyè lórí àwọn ẹ̀yà tí Israẹli:
16 Além disso, sobre as tribos de Israel: o governante dos rubenitas foi Eliézer, o filho de Zicri; dos simeonitas, Sefatias, o filho de Maaca;
17 lórí Lefi: Haṣabiah ọmọ Kemueli;
17 dos levitas: Hasabias, filho de Quemuel; dos aronitas, Zadoque;
18 lórí Juda: Elihu arákùnrin Dafidi;
18 de Judá: Eliú; um dos irmãos de Davi; de Issacar, Onri, o filho de Micael;
19 lórí Sebuluni: Iṣmaiah ọmọ Obadiah;
19 de Zebulom: Ismaías, o filho de Obadias; de Naftali, Jerimote, o filho de Azriel;
20 lórí àwọn ará Efraimu: Hosea ọmọ Asasiah;
20 dos filhos de Efraim: Oseias, o filho de Azazias; da meia tribo de Manassés, Joel, filho de Pedaías;
21 lórí ààbọ̀ ẹ̀yà Manase ní Gileadi: Iddo ọmọ Sekariah;
21 da meia tribo de Manassés, em Gileade: Ido, o filho de Zacarias; de Benjamim, Jaasiel, o filho de Abner;
22 lórí Dani: Asareeli ọmọ Jerohamu.
22 de Dã: Azarel, o filho de Jeroão. Estes foram os príncipes das tribos de Israel.
23 Dafidi kò kọ iye àwọn ọkùnrin náà ní ogún ọdún sẹ́yìn tàbí dín nítorí Olúwa ti ṣe ìlérí láti ṣe Israẹli gẹ́gẹ́ bí iye ìràwọ̀ ojú ọ̀run.
23 Porém, Davi não tomou o número daqueles com a idade de vinte anos para baixo; porque o SENHOR havia dito que multiplicaria Israel como as estrelas dos céus.
24 Joabu ọmọ Seruiah bẹ̀rẹ̀ sí ní kà wọ́n, ṣùgbọ́n kò parí kíkà wọ́n nítorí, ìbínú dé sórí àwọn Israẹli nípasẹ̀ kíka iye àti iye náà, a kò kọ ọ́ sínú ìwé ìtàn ayé ti ọba Dafidi.
24 Joabe, o filho de Zeruia, começou a enumerar, mas não terminou, porquanto, caiu ali a ira contra Israel; e o número não foi posto no registro das crônicas do rei Davi.
25 Asmafeti ọmọ Adieli wà ní ìdí ilé ìṣúra ti ọba.
25 E sobre os tesouros do rei estava Azmavete, o filho de Adiel; e sobre os armazéns nos campos, nas cidades, e nas aldeias, e nas fortalezas, estava Jônatas, o filho de Uzias;
26 Esri ọmọ Kelubu wà ní ìdí àwọn òṣìṣẹ́ lórí pápá, tí wọ́n ń ko ilẹ̀ náà.
26 e sobre aqueles que faziam o trabalho do campo para o cultivo da terra era Ezri, o filho de Quelube;
27 Ṣimei ará Ramoti wà ní ìdí àwọn ọgbà àjàrà.
27 e sobre as vinhas estava Simei, o ramatita; sobre o crescimento das vinhas para as adegas de vinho era Zabdi, o sifmita;
28 Baali-Hanani ará Gederi wà ní ìdí olifi àti àwọn igi sikamore ní apá ìhà ìwọ̀-oòrùn àwọn ní ẹ̀ṣẹ̀ pẹ̀tẹ́lẹ̀.
28 e sobre as oliveiras e os sicômoros que estavam nas planícies baixas estava Baal-Hanã, o gederita; e sobre os depósitos de azeite estava Joás;
29 Ṣitrai ará Ṣaroni wà ní ìdí fífi ọwọ́ ẹran jẹ oko ní Ṣaroni.
29 e sobre os rebanhos que pastavam em Sarom era Sitrai, o saronita; e sobre os rebanhos que estavam nos vales estava Safate, o filho de Adlai;
30 Obili ará Iṣmaeli wà ní ìdí àwọn ìbákasẹ.
30 sobre os camelos também estava Obil, o ismaelita; e sobre os jumentos estava Jedias, o meronotita;
31 Jasisi ará Hagari wà ní ìdí àwọn agbo ẹran.
31 e sobre os rebanhos estava Jaziz, o hagarita. Todos estes foram os governantes dos bens que eram do rei Davi.
32 Jonatani, arákùnrin Dafidi jẹ́ olùdámọ̀ràn, ọkùnrin onímọ̀ àti akọ̀wé.
32 Além disso, Jônatas, o tio de Davi, foi conselheiro, um homem sábio, e um escriba; e Jeiel, o filho de Hacmoni estava com os filhos do rei;
33 Ahitofeli jẹ́ olùdámọ̀ràn ọba.
33 e Aitofel era o conselheiro do rei; e Husai, o arquita era companheiro do rei;
34 (Jehoiada ọmọ Benaiah àti nípasẹ̀ Abiatari jẹ ọba rọ́pò Ahitofeli.)
34 e depois de Aitofel estava Joiada, o filho de Benaia, e Abiatar; e o general do exército do rei era Joabe.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 27, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.