1 Crônicas 26
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Àwọn ìpín tí àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà.
1 Acerca das divisões dos porteiros: dos coraítas foi Meselemias, o filho de Coré, dos filhos de Asafe.
2 Meṣelemiah ní àwọn ọmọkùnrin:
2 E os filhos de Meselemias foram: Zacarias, o primogênito; Jediael, o segundo; Zebadias, o terceiro; Jatniel, o quarto;
3 Elamu ẹlẹ́ẹ̀karùnún, Jehohanani ẹlẹ́ẹ̀kẹfà
3 Elão, o quinto; Joanã, o sexto; Elioenai, o sétimo.
4 Obedi-Edomu ni àwọn ọmọkùnrin pẹ̀lú:
4 Além disso, os filhos de Obede-Edom foram: Semaías, o primogênito; Jeozabade, o segundo; Joá, o terceiro; e Sacar, o quarto; e Natanael, o quinto;
5 Ammieli ẹ̀kẹfà,
5 Amiel, o sexto; Issacar, o sétimo; Peuletai, o oitavo; porque Deus o abençoou.
6 Ọmọ rẹ̀ Ṣemaiah ní àwọn ọmọkùnrin pẹ̀lú tí wọ́n jẹ́ olórí ní ìdílé baba a wọn nítorí wọ́n jẹ́ ọkùnrin tó lágbára.
6 Também a seu filho Semaías nasceram filhos que governaram toda a casa do seu pai; porque eram homens fortes e valentes.
7 Àwọn ọmọ Ṣemaiah:
7 Os filhos de Semaías: Otni, e Rafael, e Obede, e Elzabade; cujos irmãos, Eliú e Semaquias, eram homens fortes.
8 Gbogbo wọ̀nyí ní ìran ọmọ Obedi-Edomu; àwọn àti ọmọkùnrin àti ìbátan wọn jẹ́ alágbára ọkùnrin pẹ̀lú ipá láti ṣe ìsìn náà. Ìran Obedi-Edomu méjìlélọ́gọ́ta ni gbogbo rẹ̀.
8 Todos estes dos filhos de Obede-Edom; eles e seus filhos e seus irmãos, homens aptos para força e para o serviço, eram sessenta e dois de Obede-Edom.
9 Meṣelemiah ní àwọn ọmọ àti àwọn ìbátan, tí ó jẹ́ alágbára méjìdínlógún ni gbogbo wọn.
9 E Meselemias teve filhos e irmãos, dezoito homens fortes.
10 Hosa ará Merari ní àwọn ọmọkùnrin:
10 Também Hosa, dos filhos de Merari, teve filhos: Sinri, o chefe (pois embora ele não fosse o primogênito, o seu pai fez dele, mesmo assim, chefe);
11 Hilkiah ẹlẹ́ẹ̀kejì, Tabaliah ẹ̀kẹta
11 Hilquias, o segundo; Tebalias, o terceiro, Zacarias, o quarto; todos os filhos e irmãos de Hosa foram treze.
12 Ìpín wọ̀nyí ti àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà nípasẹ̀ olóyè ọkùnrin wọn, ní iṣẹ́ ìsìn fún jíjíṣẹ́ nínú ilé Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ìbátan wọn ti ṣe.
12 Entre estes estavam as divisões dos porteiros, a saber; entre os principais, tendo guardas um diante do outro, para ministrar na casa do SENHOR.
13 Wọ́n ṣẹ́ kèké fún ẹnu-ọ̀nà kọ̀ọ̀kan gẹ́gẹ́ bí àwọn ìdílé wọn bí ọ̀dọ́ àti arúgbó.
13 E eles lançaram sorte, tanto os pequenos como os grandes, segundo a casa dos seus pais, para cada portão.
14 Kèké fún ẹnu-ọ̀nà ilà oòrùn bọ́ sí ọ̀dọ̀ Ṣelemiah.
14 E a sorte oriental caiu para Selemias. Então, para Zacarias, o seu filho, um sábio conselheiro, lançaram sorte; e a sua sorte saiu para o norte.
15 Kèké fún ẹnu-ọ̀nà ìhà gúúsù bọ́ sí ọ̀dọ̀ Obedi-Edomu, kèké fún ilé ìṣúra sì bọ́ sí ọ̀dọ̀ ọmọ rẹ̀.
15 Para Obede-Edom o lado sul; e aos seus filhos, as casas dos depósitos.
16 Kèké fún ẹnu-ọ̀nà ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Ṣaleketi ẹnu-ọ̀nà ní ọ̀nà apá òkè bọ́ sí ọ̀dọ̀ Ṣuppimu àti Hosa.
16 Para Supim e Hosa a sorte saiu na parte ocidental, com o portão Salequete, perto da estrada que sobe, guarda diante de guarda.
17 Àwọn ará Lefi mẹ́fà ní ó wà ní ọjọ́ kan ní ìhà ìlà-oòrùn,
17 No lado oriental estavam seis levitas, no lado norte quatro por dia, no lado sul quatro por dia, porém para as casas dos depósitos de dois em dois.
18 Ní ti ilé ẹjọ́ sí ìhà ìwọ̀-oòrùn, mẹ́rin sì wà ní ojú ọ̀nà àti méjì ní ilé ẹjọ́ fúnra rẹ̀.
18 Em Parbar, no lado ocidental, quatro no caminho elevado, e dois em Parbar.
19 Wọ̀nyí ni ìpín ti àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà tí wọ́n jẹ́ àwọn ìran ọmọ Kora àti Merari.
19 Estas são as divisões dos porteiros entre os filhos de Coré, e entre os filhos de Merari.
20 Láti inú àwọn ọmọ Lefi, Ahijah ni ó wà lórí ìṣúra ti ilé Ọlọ́run àti lórí ìṣúra nǹkan wọ̀n-ọn-nì tí a yà sí mímọ́.
20 E dos levitas, Aías estava a cargo dos tesouros da casa de Deus, e a cargo dos tesouros das coisas sagradas.
21 Àwọn ìran ọmọ Laadani tí wọn jẹ́ ará Gerṣoni nípasẹ̀ Laadani àti tí wọn jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé tí ó jẹ́ ti Laadani ará Gerṣoni ni Jehieli.
21 Os filhos de Ladã, os filhos do gersonita Ladã, pais chefes de Ladã, o gersonita, foram: Jeieli.
22 Àwọn ọmọ Jehieli, Setamu àti arákùnrin rẹ̀ Joẹli. Wọ́n ṣalábojútó ilé ìṣúra ti ilé ìṣúra ti ilé Olúwa.
22 Os filhos de Jeieli: Zetã, e Joel, seu irmão, os quais estavam a cargo dos tesouros da casa do SENHOR.
23 Láti ọ̀dọ̀ àwọn ará Amramu, àwọn ará Isari, àwọn ará Hebroni àti àwọn ará Usieli.
23 Dos anramitas, e dos izaritas, dos hebronitas, e dos ozielitas,
24 Ṣubaeli, ìran ọmọ Gerṣomu ọmọ Mose jẹ́ olórí tí ó bojútó ilé ìṣúra.
24 e Sebuel, o filho de Gérson, o filho de Moisés, era governante dos tesouros.
25 Àwọn ìbátan rẹ̀ nípasẹ̀ Elieseri: Rehabiah ọmọ rẹ̀, Jeṣaiah ọmọ rẹ̀, Joramu ọmọ rẹ̀, Sikri ọmọ rẹ̀, Ṣelomiti ọmọ rẹ̀.
25 E os seus irmãos por Eliézer: Reabias, seu filho; e Jesaías, seu filho; e Jorão, seu filho; e Zicri, seu filho; e Selomite, seu filho;
26 Ṣelomiti àti àwọn ìbátan rẹ̀ jẹ́ alábojútó ilé ìṣúra fún àwọn ohun tí à ti yà sọ́tọ̀ nípa ọba Dafidi, nípasẹ̀ àwọn olórí àwọn ìdílé tí wọ́n jẹ́ alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún àti nípasẹ̀ alákòóso ọmọ-ogun mìíràn.
26 Este Selomite e seus irmãos estavam a cargo de todos os tesouros das coisas sagradas; as quais Davi, o rei, e os pais chefes, os capitães sobre milhares e centúrias, e os capitães do exército, tinham consagrado.
27 Díẹ̀ nínú ìkógun tí wọ́n kó nínú ogun ni wọ́n yà sọ́tọ̀ fún títún ilé Olúwa ṣe.
27 Dos despojos ganhos em batalhas eles dedicavam para manter a casa do SENHOR.
28 Pẹ̀lú gbogbo nǹkan tí a yà sọ́tọ̀ láti ọ̀dọ̀ Samuẹli aríran láti nípasẹ̀ Saulu ọmọ Kiṣi, Abneri ọmọ Neri àti Joabu ọmọ Seruiah gbogbo ohun tí a yà sọ́tọ̀ sì wà ní abẹ́ ìtọ́jú Ṣelomiti àti àwọn ìbátan rẹ̀.
28 E tudo o que Samuel, o vidente, e Saul, o filho de Quis, e Abner, o filho de Ner, e Joabe, o filho de Zeruia, tinham consagrado; e quem quer que houvesse consagrado alguma coisa, estava isto sob a mão de Selomite, e dos seus irmãos.
29 Láti ọ̀dọ̀ àwọn Isari:
29 Dos izaritas, Quenanias e seus filhos foram postos para os negócios externos sobre Israel, como oficiais e juízes.
30 Láti ọ̀dọ̀ àwọn Hebroni:
30 E dos hebronitas; Hasabias e seus irmãos, homens valentes, mil e setecentos, tinham a seu cargo a Israel além do Jordão para o ocidente, em todos os negócios do SENHOR, e no serviço do rei.
31 Ní ti àwọn ará Hebroni, Jeriah jẹ́ olóyè wọn gẹ́gẹ́ bí ìwé ìrántí ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, ní ti ìdílé wọn.
31 Entre os hebronitas estava Jerias, o chefe, a saber, no meio dos hebronitas, segundo as gerações dos pais dele. No quadragésimo ano do reinado de Davi eles foram procurados, e foram encontrados ali entre os homens fortes e valentes em Jazer de Gileade.
32 Jeriah ní ẹgbẹ̀rún méjì ó lé ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin (2,700) ìbátan, tí wọn jẹ́ ọkùnrin alágbára àti olórí àwọn ìdílé ọba Dafidi sì fi wọ́n ṣe àkóso lórí àwọn ará Reubeni àwọn ará Gadi àti ààbọ̀ ẹ̀yà ti Manase fún gbogbo ọ̀rọ̀ tí ó jọ mọ́ ti Ọlọ́run àti fún ọ̀ràn ti ọba.
32 E os seus irmãos, homens valentes, eram dois mil e setecentos pais chefes, aos quais o rei Davi fez governantes sobre os rubenitas, sobre os gaditas, e sobre a meia tribo de Manassés, para todos os assuntos pertencentes a Deus, e aos negócios do rei.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 26, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.