1 Crônicas 25
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Pẹ̀lúpẹ̀lú Dafidi àti àwọn olórí àwọn ọmọ-ogun, ó sì yà díẹ̀ sọ́tọ̀ lára àwọn ọmọ Asafu, Hemani àti Jedutuni fún ìsìn àsọtẹ́lẹ̀, pẹ̀lú dùùrù, ohun èlò orin olókùn àti kimbali. Èyí sì ní àwọn iye àwọn ọkùnrin ẹni tí ó ṣe oníṣẹ́ ìsìn yìí.
1 Além disso, Davi e os capitães do exército separaram para o serviço alguns dos filhos de Asafe, e de Hemã, e de Jedutum, que deveriam profetizar com harpas, com saltérios, e com címbalos; e o número dos trabalhadores, segundo o seu serviço, era:
2 Nínú àwọn ọmọ Asafu:
2 dos filhos de Asafe: Zacur, e José, e Netanias, e Asarela, os filhos de Asafe, sob as mãos de Asafe, o qual profetizava segundo a ordem do rei.
3 Gẹ́gẹ́ bí ti Jedutuni, nínú àwọn ọmọkùnrin rẹ̀:
3 De Jedutum: os filhos de Jedutum; Gedalias, e Zeri, e Jesaías, Hasabias, e Matitias, seis, sob as mãos do seu pai, Jedutum, que profetizava com uma harpa, para dar graças e louvor ao SENHOR.
4 Gẹ́gẹ́ bí ti Hemani, nínú àwọn ọmọ rẹ̀:
4 De Hemã: os filhos de Hemã; Buquias, Matanias, Uziel, Sebuel, Jerimote, Hananias, Hanani, Eliata, Gidalti, Romanti-Ézer, Josbecasa, Maloti, Hotir, e Maaziote;
5 Gbogbo àwọn wọ̀nyí sì ni ọmọ Hemani àti wòlíì ọba. Wọ́n sì fi wọ́n fún nípa ìlérí Ọlọ́run láti máa gbé ìwo sókè. Ọlọ́run sì fún Hemani ní ọmọkùnrin mẹ́rìnlá àti àwọn ọmọbìnrin mẹ́ta.
5 todos estes eram os filhos de Hemã, o vidente do rei nas palavras de Deus, para erguer o chifre. E Deus deu a Hemã, catorze filhos e três filhas.
6 Gbogbo àwọn ọkùnrin yìí ni wọ́n wà lábẹ́ ìbojútó àwọn baba wọn fún ohun èlò orin ilé Olúwa, pẹ̀lú kimbali, ohun èlò orin olókùn àti dùùrù, fún ìsìn ilé Olúwa.
6 Todos estes estiveram debaixo das mãos do seu pai para cânticos na casa do SENHOR, com címbalos, saltérios, e harpas para o serviço da casa de Deus, segundo a ordem do rei a Asafe, Jedutum e Hemã.
7 Àwọn ìdílé wọn pẹ̀lú gbogbo àwọn tí ó mòye àti àwọn tí a kọ́ ní ohun èlò orin fún Olúwa, iye wọn sì jẹ́ ọ̀rìnlélúgba ó lé mẹ́jọ (288).
7 Então, o número deles, com os seus irmãos que eram instruídos nos cânticos do SENHOR, a saber, todos os que eram peritos, era de duzentos e oitenta e oito.
8 Kékeré àti àgbà bákan náà, olùkọ́ àti gẹ́gẹ́ bí ti akẹ́kọ̀ọ́, ṣẹ́ kèké fún iṣẹ́ wọn.
8 E eles lançaram sorte, guarda contra guarda, tanto o pequeno como o grande, tanto o mestre quanto o discípulo.
9 Kèké èkínní èyí tí ó jẹ́ ti Asafu, jáde sí Josẹfu, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
9 Ora, a primeira sorte saiu por Asafe para José; a segunda para Gedalias, que, com os seus irmãos e filhos eram doze;
10 ẹlẹ́ẹ̀kẹta sí Sakkuri, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé, méjìlá
10 a terceira para Zacur, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
11 ẹlẹ́ẹ̀kẹrin sí Isiri, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
11 a quarta para Izri, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
12 ẹlẹ́ẹ̀karùnún sí Netaniah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
12 a quinta para Netanias, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
13 ẹlẹ́ẹ̀kẹfà sí Bukkiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
13 a sexta para Buquias, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
14 ẹlẹ́ẹ̀keje sí Jasarela, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
14 a sétima para Jesarela, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
15 ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ sí Jeṣaiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
15 a oitava para Jesaías, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
16 ẹlẹ́ẹ̀kẹsàn-án sí Mattaniah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
16 a nona para Matanias, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
17 ẹlẹ́ẹ̀kẹwàá sí Ṣimei, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ jẹ́, méjìlá
17 a décima para Simei, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
18 ẹlẹ́ẹ̀kọkànlá sí Asareeli, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
18 a undécima para Azarel, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
19 ẹlẹ́ẹ̀kẹjìlá sí Haṣabiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
19 a duodécima para Hasabias, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
20 ẹlẹ́ẹ̀kẹtàlá sí Ṣubaeli, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
20 a décima terceira para Subael, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
21 ẹlẹ́ẹ̀kẹrìnlá sí Mattitiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
21 a décima quarta para Matitias, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
22 ẹlẹ́ẹ̀kẹẹ̀dógún sí Jerimoti, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
22 a décima quinta para Jerimote, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
23 ẹlẹ́ẹ̀kẹrìndínlógún sí Hananiah, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
23 a décima sexta para Hananias, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
24 ẹlẹ́ẹ̀kẹtàdínlógún sí Joṣbekaṣa, àwọn ọmọ rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
24 a décima sétima para Josbecasa, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
25 ẹlẹ́ẹ̀kejìdínlógún sí Hanani, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
25 a décima oitava para Hanani, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
26 ẹlẹ́ẹ̀kọkàndínlógún sí Malloti, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
26 a décima nona para Maloti, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
27 ogún sí Eliata, àwọn ọmọ rẹ̀ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
27 a vigésima para Eliata, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
28 ẹlẹ́ẹ̀kọkànlélógún sí Hotiri, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
28 a vigésima primeira para Hotir, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
29 ẹlẹ́ẹ̀kejìlélógún sí Giddalti, àwọn ọmọ rẹ̀ àti àwọn ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
29 a vigésima segunda para Gidalti, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
30 ẹlẹ́ẹ̀kẹtàlélógún sí Mahasiotu, àwọn ọmọ rẹ àti ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá
30 a vigésima terceira para Maaziote, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze;
31 ẹlẹ́ẹ̀kẹrìnlélógún sí Romamtieseri àwọn ọmọ rẹ̀, àti àwọn ìdílé rẹ̀ sì jẹ́, méjìlá.
31 a vigésima quarta para Romanti-Ézer, ele, os seus filhos, e os seus irmãos, eram doze.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 25, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.