1 Crônicas 18
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH
1 Ní àkókò kan, Dafidi kọlu àwọn ará Filistini, ó sì ṣẹ́gun wọn. Ó sì mú Gati àti àwọn ìletò agbègbè rẹ̀ kúrò lábẹ́ ìdarí àwọn ará Filistini.
1 Algum tempo depois, Davi atacou de novo os filisteus e os derrotou. Tomou deles a cidade de Gate e os povoados que ficavam ao seu redor.
2 Dafidi borí àwọn ará Moabu, wọ́n sì di ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọ́n sì mú owó òde wá.
2 Também derrotou os moabitas, que ficaram dominados por ele e lhe pagavam impostos.
3 Síbẹ̀, Dafidi sì kọlu Hadadeseri ọba Soba ní Hamati, bí ó ti ń lọ láti fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ létí odò Eufurate.
3 Depois Davi atacou Hadadezer, que era o rei de Zoba, na Síria, perto da região de Hamate. Isso aconteceu quando Hadadezer estava tentando conquistar a região que ficava ao longo do rio Eufrates.
4 Dafidi fi agbára gba ẹgbẹ̀rún (1,000) kẹ̀kẹ́ rẹ̀, ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin (7,000) agun-kẹ̀kẹ́ àti ogún ẹgbẹ̀rún (20,000) ológun ilẹ̀. Ó sì já gbogbo ọgọ́rùn-ún iṣan ẹsẹ̀ àwọn kẹ̀kẹ́-ẹṣin náà.
4 Davi tomou de Hadadezer mil carros de guerra e prendeu sete mil cavaleiros e vinte mil soldados de infantaria. Ele também ficou com cavalos suficientes para puxarem cem carros de guerra e aleijou os outros.
5 Nígbà ti àwọn ará Siria ti Damasku wá láti ran Hadadeseri ọba Soba lọ́wọ́, Dafidi lu ẹgbẹ̀rún méjìlélógún (22,000) wọn bọ lẹ̀.
5 Os sírios de Damasco foram socorrer Hadadezer, e Davi os atacou e matou vinte e dois mil deles.
6 Ó sì fi àwọn ọ̀wọ́ ọmọ-ogun rẹ sínú ìjọba Siria ti Damasku, àwọn ará Siria sì ń sìn ní abẹ́ rẹ̀, wọ́n sì mú owó ìṣákọ́lẹ̀ wá. Olúwa sì ń fún Dafidi ní ìṣẹ́gun ní ibi gbogbo tí ó bá lọ.
6 Em seguida colocou acampamentos militares no território dos sírios de Damasco. Davi os dominou, e eles lhe pagavam impostos. O Senhor Deus fez com que Davi fosse vitorioso em todos os lugares.
7 Dafidi mú àpáta wúrà tí àwọn ìjòyè Hadadeseri gbé, ó sì gbé wọn wá sí Jerusalẹmu.
7 Davi tomou dos oficiais de Hadadezer os escudos de ouro que eles usavam e os levou para Jerusalém.
8 Láti Tibhati àti Kuni, àwọn ìlú Hadadeseri, Dafidi kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ idẹ tí Solomoni lò láti fi ṣe okùn idẹ, àwọn òpó àti oríṣìí ohun èlò idẹ.
8 Também tomou uma grande quantidade de bronze das cidades de Tibate e de Cum, que eram governadas por Hadadezer. (Anos mais tarde, Salomão usou esse bronze para fazer o tanque, as colunas e objetos para o Templo.)
9 Nígbà tí Tou ọba Hamati gbọ́ pé Dafidi ti borí gbogbo ọmọ-ogun Hadadeseri ọba Soba.
9 O rei Toí, da cidade de Hamate, soube que Davi tinha derrotado todo o exército de Hadadezer.
10 Ó rán ọmọ rẹ̀ Hadoramu sí ọba Dafidi láti kí i àti láti lọ bá a yọ̀ lórí ìṣẹ́gun rẹ̀ nínú ogun lórí Hadadeseri, tí ó wà lójú ogun pẹ̀lú Tou. Hadoramu mú oríṣìíríṣìí ohun èlò ti wúrà àti fàdákà àti idẹ wá.
10 Então mandou o seu filho Jorão para cumprimentar Davi e para lhe dar os parabéns por ter vencido Hadadezer. Acontece que Toí havia lutado muitas vezes contra Hadadezer. Jorão levou para Davi objetos de prata, de ouro e de bronze.
11 Ọba Dafidi ya ohun èlò wọ́n yí sí mímọ́ fún Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe pẹ̀lú fàdákà àti wúrà tí ó ti mú láti gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí: Edomu àti Moabu, ará Ammoni àti àwọn ará Filistini àti Amaleki.
11 E o rei Davi os separou para serem usados na adoração a Deus, o Senhor , juntamente com a prata e o ouro que tinha tomado dos povos que havia conquistado, isto é, os edomitas, os moabitas, os amonitas, os filisteus e os amalequitas.
12 Abiṣai ọmọ Seruiah lu ẹgbàá mẹ́sàn (18,000) ará Edomu bolẹ̀ ní àfonífojì Iyọ̀.
12 Abisai, cuja mãe se chamava Zeruia, derrotou os edomitas no vale do Sal e matou dezoito mil deles.
13 Ó fi ẹgbẹ́ ogun sí Edomu, gbogbo àwọn ará Edomu sì ń sìn ní abẹ́ Dafidi. Olúwa fún Dafidi ní ìṣẹ́gun ní gbogbo ibí tí ó bá lọ.
13 Ele colocou acampamentos militares em todo o país de Edom, e o povo dali ficou debaixo do domínio de Davi. O Senhor fez com que Davi fosse vitorioso em todos os lugares aonde ia.
14 Dafidi jẹ ọba lórí gbogbo Israẹli, ó sì ṣe òdodo àti ohun tí ó yẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀.
14 Davi governou todo o Israel e fez com que o seu povo fosse sempre tratado com justiça.
15 Joabu ọmọ Seruiah jẹ́ olórí ẹgbẹ́ ọmọ-ogun;
15 Joabe, irmão de Abisai, era o comandante do exército. Josafá, filho de Ailude, era conselheiro do rei.
16 Sadoku ọmọ Ahitubu àti Abimeleki ọmọ Abiatari jẹ́ àwọn àlùfáà;
16 Zadoque, filho de Aitube, e Aimeleque, filho de Abiatar, eram sacerdotes. Seraías era o escrivão.
17 Benaiah ọmọ Jehoiada jẹ́ olórí àwọn Kereti àti Peleti;
17 Benaías, filho de Joiada, era o chefe dos queretitas e dos peletitas . E os filhos do rei Davi tinham as mais altas posições no seu serviço.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 18, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.