1 Crônicas 17
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs BKJ
1 Lẹ́yìn ìgbà tí Dafidi ti fi ìdí kalẹ̀ sínú ààfin rẹ̀, ó sọ fún Natani wòlíì pé, “Èmi nìyí, tí ń gbé inú ààfin kedari nígbà tí àpótí ẹ̀rí Olúwa wà lábẹ́ àgọ́.”
1 Ora, sucedeu, enquanto estava assentado na sua casa, que Davi disse a Natã, o profeta: Eis que eu habito em uma casa de cedros, mas a arca do pacto do SENHOR permanece debaixo de cortinas.
2 Natani dá Dafidi lóhùn pé, “Ohunkóhun tí o bá ní lọ́kàn, ṣe é nítorí tí Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ.”
2 Então, Natã disse a Davi: Faz tudo o que está no teu coração; porque Deus está contigo.
3 Ní àṣálẹ́ ọjọ́ náà, ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tọ Natani wá, wí pé:
3 E sucedeu, naquela mesma noite, que a palavra de Deus veio a Natã, dizendo:
4 “Lọ sọ fún ìránṣẹ́ mi Dafidi, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Ìwọ kò gbọdọ̀ kọ́ ilé fún mi láti máa gbé.
4 Vai e diz a Davi, o meu servo: Assim diz o SENHOR: Tu não edificarás para mim uma casa na qual eu habite;
5 Èmi kò tí ì gbé nínú ilé láti ọjọ́ tí mo ti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti títí di òní yìí. Èmi ń lọ láti àgọ́ dé àgọ́ àti láti ibùgbé dé ibùgbé.
5 Porque até este dia, não tenho habitado em uma casa desde o dia que fiz subir Israel; mas tenho ido de tenda em tenda, e de um tabernáculo a outro.
6 Ni ibi gbogbo tí mo ti bá gbogbo Israẹli rìn dé, ǹjẹ́ mo wí nǹkan kan sí ọ̀kan nínú àwọn adarí Israẹli, tí èmí pàṣẹ fún láti máa jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn àwọn ènìyàn mi, wí pé, “Kí ní ṣe tí ẹ̀yin kò fi kọ́ ilé tí a fi igi kedari kọ́ fún mi?” ’
6 Onde quer que eu tenha caminhado com todo o Israel, falei alguma palavra a qualquer dos juízes de Israel, aos quais ordenei que alimentassem o meu povo, dizendo: Por que não edificastes para mim uma casa de cedros?
7 “Nígbà náà, sọ fún ìránṣẹ́ mi Dafidi pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: Èmi mú ọ kúrò ní pápá oko tútù wá, àní kúrò lẹ́yìn agbo àgùntàn, kí ìwọ kí ó lè máa ṣe olórí àwọn ènìyàn mi Israẹli.
7 Agora, portanto, assim dirás ao meu servo Davi: Assim diz o SENHOR dos Exércitos: Eu te tirei do aprisco, do pastoreio das ovelhas, para ser soberano sobre o meu povo, Israel;
8 Èmi ti wà pẹ̀lú rẹ ní, ibikíbi tí ìwọ bá lọ, èmí sì ti gé gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ kúrò níwájú rẹ. Nísinsin yìí Èmi yóò mú kí orúkọ rẹ kí ó dàbí orúkọ àwọn ènìyàn ńlá jùlọ tí ó wà ní ayé.
8 e tenho estado contigo onde quer que tenhas andado; e tenho cortado todos os teus inimigos de diante de ti, e tenho feito para ti um nome semelhante o nome dos grandes homens que estão na terra.
9 Èmi yóò sì pèsè ààyè kan fún àwọn ènìyàn mi Israẹli, kí wọn kí ó lè ní ilé tiwọn, kí a má sì ṣe dààmú wọn mọ́. Àwọn ènìyàn búburú kì yóò ni wọ́n lára mọ́, gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ṣe ní ìbẹ̀rẹ̀.
9 Também ordenarei um lugar para o meu povo, Israel, e haverei de plantá-los, e eles habitarão no seu lugar, e não mais serão removidos; tampouco os filhos da iniquidade voltarão a se aproveitar deles, como no princípio,
10 Bí wọ́n sì ti ṣe láti ìgbà tí mo ti yan àwọn aṣáájú lórí àwọn ènìyàn mi Israẹli. Èmi pẹ̀lú yóò ṣẹ́gun gbogbo àwọn ọ̀tá yín.
10 e desde o tempo em que eu ordenei aos juízes para estarem acima do meu povo, Israel. Além disso, subjugarei todos os teus inimigos. Sobretudo, digo-te que o SENHOR edificará para ti uma casa.
11 nígbà ti ọjọ́ rẹ bá kọjá, tí ìwọ bá lọ láti lọ bá àwọn baba à rẹ, Èmi yóò gbé àwọn ọmọ rẹ sókè láti rọ́pò rẹ, ọ̀kan lára àwọn ọmọ tìrẹ, Èmi yóò sì fìdí ìjọba rẹ̀ kalẹ̀.
11 E sucederá, quando estiverem expirados os teus dias, quando tiveres que ir para estar com os teus pais, que levantarei a tua semente após ti, a qual será dos teus filhos; e eu estabelecerei o seu reino.
12 Òun ni ẹni tí yóò kọ́ ilé fún mi, èmi yóò sí fi ìdí ìtẹ́ rẹ̀ kalẹ̀ títí láé.
12 Ele edificará uma casa para mim, e eu estabelecerei o seu trono para sempre.
13 Èmi yóò jẹ́ baba rẹ̀, Òun yóò sì jẹ́ ọmọ mi. Èmi kì yóò mú ìfẹ́ mi kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ láéláé gẹ́gẹ́ bí mo ṣe mú un kúrò lọ́dọ̀ àwọn aṣáájú rẹ̀.
13 Eu serei o seu pai, e ele será o meu filho; e não removerei a minha misericórdia dele, como a removi daquele que esteve antes de ti;
14 Èmi yóò gbé e ka orí ilé mi àti ìjọba mi títí láé; ìtẹ́ rẹ̀ ni a ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ títí láé.’ ”
14 mas eu o assentarei na minha casa e no meu reino para sempre; e o seu trono será estabelecido para todo o sempre.
15 Natani ròyìn fún Dafidi gbogbo àwọn ọ̀rọ̀ ti ìfihàn yí.
15 De acordo com todas estas palavras, e de acordo com toda esta visão, assim falou Natã a Davi.
16 Nígbà náà, ọba Dafidi wọlé lọ, ó sì jókòó níwájú Olúwa ó sì wí pé,
16 E o rei Davi, entrou, e se assentou diante do SENHOR, e disse: Quem sou eu, ó SENHOR Deus? O que é a minha casa, para que me tenhas trazido até aqui?
17 Pẹ̀lú bí ẹni pé èyí kò tó lójú rẹ, Ọlọ́run, ìwọ ti sọ̀rọ̀ nípa ọjọ́ iwájú ilé ìránṣẹ́ rẹ. Ìwọ ti wò mí bí ẹni pé èmi ni ẹni gbígbéga jù láàrín àwọn ọkùnrin Olúwa Ọlọ́run.
17 E, contudo, isto foi pouca coisa aos teus olhos, ó Deus; pois tu tens falado da casa do teu servo para um distante no porvir, e tens me respeitado como um homem de alto nível, ó SENHOR Deus.
18 “Kí ni ohun tí Dafidi tún lè sọ nítorí ọlá tí o bù fún ìránṣẹ́ rẹ? Nítorí tí ìwọ mọ ìránṣẹ́ rẹ,
18 O que mais Davi pode falar a ti para a honra do teu servo? Porque tu conheces o teu servo.
19 Olúwa. Nítorí ti ìránṣẹ́ rẹ àti gẹ́gẹ́ bí àṣẹ rẹ, ìwọ ti ṣe ohun ńlá yìí àti láti fi gbogbo ìlérí ńlá yìí hàn.
19 Ó SENHOR, por causa do teu servo, e segundo o teu próprio coração, tu tens feito toda esta grandeza, ao tornares conhecidas todas estas grandes coisas.
20 “Kò sí ẹnìkan bí rẹ Olúwa, kò sì sí Ọlọ́run kan àfi ìwọ, gẹ́gẹ́ bí à ti gbọ́ pẹ̀lú etí ara wa.
20 Ó SENHOR, pois não há nenhum como tu, nem há qualquer Deus ao teu lado, segundo tudo o que temos ouvido com os nossos ouvidos.
21 Pẹ̀lú ta ni ó dàbí àwọn ènìyàn rẹ Israẹli—orílẹ̀-èdè kan ní ayé, tí Ọlọ́run jáde lọ láti ra àwọn ènìyàn kan padà fún ara rẹ̀, àti láti lè ṣe orúkọ fún ara à rẹ, àti láti ṣe ohun ńlá àti ọwọ́ ìyanu nípa lílé àwọn orílẹ̀-èdè kúrò níwájú àwọn ènìyàn rẹ̀, ẹni tí ó gbàlà láti Ejibiti?
21 E que nação na terra é como o teu povo Israel, ao qual Deus foi redimir para ser o seu próprio povo, para fazer um nome de grandeza e temor para ti, ao expulsares nações de diante do teu povo, o qual tens redimido do Egito?
22 Ìwọ ṣe àwọn ènìyàn rẹ Israẹli ní tìrẹ láéláé ìwọ Olúwa sì ti di Ọlọ́run wọn.
22 Porque do teu povo, Israel, fizeste o teu próprio povo para sempre; e tu, SENHOR, tornaste-te o seu Deus.
23 “Nísinsin yìí, Olúwa, jẹ́ kí ìlérí tí ìwọ ti ṣe fún ìránṣẹ́ rẹ àti ilé rẹ̀ di fífi ìdí múlẹ̀ títí láé. Ṣe gẹ́gẹ́ bí o ti ṣe ìlérí.
23 Portanto, agora, SENHOR, que a palavra que tens falado acerca do teu servo e acerca da sua casa seja estabelecida para sempre, e faz conforme tens dito.
24 Kí ó lè di fífi ìdí múlẹ̀ àti kí orúkọ rẹ di gbígbéga títí láé. Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin yóò wí pé, ‘Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ni Ọlọ́run Israẹli.’ Ilé ìránṣẹ́ rẹ Dafidi sì ni a ó fi ìdí rẹ̀ múlẹ̀ níwájú rẹ.
24 Que, de fato, seja estabelecido, que o teu nome possa ser magnificado para sempre, e diga-se: O SENHOR dos Exércitos é o Deus de Israel, é o Deus para Israel; e que a casa de Davi, o teu servo, seja estabelecida diante de ti.
25 “Ìwọ, Ọlọ́run mi, ti fihan ìránṣẹ́ rẹ pé, ìwọ yóò kọ́ ilé fún un. Bẹ́ẹ̀ ni ìránṣẹ́ rẹ ti ní ìgboyà láti gbàdúrà sí ọ.
25 Porque tu, ó meu Deus, disseste ao teu servo que edificarás para ele uma casa; porquanto o teu servo achou valor no seu coração para orar diante de ti.
26 Olúwa, ìwọ ni Ọlọ́run. Ìwọ ti fi ìlérí dídára yìí fún ìránṣẹ́ rẹ.
26 E, agora, SENHOR, tu és Deus, e tens prometido a tua bondade ao teu servo.
27 Nísinsin yìí ó ti tẹ́ ọ lọ́rùn láti bùkún ilé ìránṣẹ́ rẹ kí ó lè tẹ̀síwájú ní ojú rẹ; nítorí ìwọ, Olúwa, ti bùkún un, a ó sì bùkún un títí láéláé.”
27 Agora, portanto, foste servido abençoar a casa do teu servo, para que ela possa estar diante de ti para sempre; porque tu abençoas, ó SENHOR, e ela será abençoada para sempre.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Crônicas 17, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.