1 Coríntios 9
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Èmi kò ha ni òmìnira bí? Èmi kò ha ń ṣe aposteli bí? Èmi kò ha ti rí Jesu Olúwa bí? Ẹ̀yìn ha kọ́ ní èrè iṣẹ́ mi nínú Olúwa bí?
1 Kwanotanot ayu i fatufatum wanawanan ama’am? Naatu kwanotanot ayu i men Regah ana tur abarayan? Naatu ata Regah Jesu Keriso men aitin? Naatu kwanotanot kwa i men ayu au abowabow ana ro’on?
2 Ní ìrònú àwọn ẹlòmíràn, èmi kì í ṣe aposteli. Dájúdájú aposteli ni mo jẹ́ fún un yín, tí n kì bá ṣe fún àwọn ẹlòmíràn. Nítorí èdìdì iṣẹ́ aposteli mi ni ẹ̀yin jẹ́ nínú Olúwa.
2 Sabuw afa ayu men tur abarayan na’atube hinabubuwu na’at, baise kwa boro ayu kwanabuwu, anayabin kwa ayawas Regah wanawananamaim ebi’obaiyi, turobe kwa i ayu au bowabow ana ro’on, imih ayu i Regah ana tur abarayan.
3 Èyí ni ìdáhùn mi sí àwọn tí ń béèrè ẹ̀tọ́ aposteli mi.
3 Sabuw ayu tegam tiu’uwu ana maramaim ayu iti na’atube ao awawasfafaru.
4 Ṣé a kò ní ẹ̀tọ́ láti máa jẹ àti láti máa mu bí?
4 Aki a bowabow isan ai ef ema’am boro anaa, anatom ai en?
5 Ṣé àwa kò ní ẹ̀tọ́ láti máa mú ìyàwó tí í ṣe onígbàgbọ́ káàkiri gẹ́gẹ́ bí àwọn aposteli mìíràn? Àti bí arákùnrin Olúwa, àti Kefa.
5 Ai ef ema’am karam boro toutabin babin baitumatumayah bairi anaremor, tur abarayah, afa ata Regah Jesu taitin naatu Cephas tisisinaf na’atube ai en?
6 Ṣé èmi nìkan àti Barnaba, àwa kò ha ní agbára láti máa ṣiṣẹ́ bọ́ ara wa ni?
6 Ai ayu Barnabas airi’imo, ai aa ai tom isan anama anabow?
7 Ta ni ó ṣíṣẹ́ ológun tí ó sanwó ara rẹ̀? Ta ní gbin ọgbà àjàrà tí kì í jẹ nínú èso rẹ̀? Tàbí ta ní ń bọ ọ̀wọ́ ẹran tí kì í sí ì jẹ nínú wàrà ọ̀wọ́ ẹran?
7 Baiyowayan orot ebowabow men i taiyuwin ana baiyan ebitin. Naatu orot yait masaw bowayan ana masawamaim grape ro’oro’on boro nirut, naatu bobaituw kaifenayah ana cow hai nun boro natom.
8 Èmi ha sọ nǹkan wọ̀nyí bí ènìyàn? Tàbí òfin kò wí bákan náà bì?
8 Ayu men orot ana roubabaruwen fairamaim ao’omih, anayabin God ana obaiyunen tur i ta’imon nati na’atube eo ema’am.
9 Nítorí nínú òfin tí Ọlọ́run fún Mose, ni a tí kọ ọ́ pé, “Ìwọ kò gbọdọ̀ di màlúù ti ń tẹ ọkà lẹ́nu.” Ǹjẹ́ màlúù ni Ọlọ́run n ṣe ìtọ́jú rẹ̀ bi?
9 Moses ana ofafaramaim kikirum iti na’atube eo “Bobaituw wabin ox sanabey nawawas kweyakweyaren ana veya men awan kwana’utan.” God iti na’atube eo’o kwanotanot i ox isan eo?
10 Dájúdájú ó sọ eléyìí fún wa pé, nítorí wa ni a ṣe kọ̀wé yìí kí ẹni tí ń tulẹ̀ lè máa tulẹ̀ ní ìrètí àti ẹni tí ń pakà lè ni ìrètí láti ní ìpín nínú ìkórè.
10 En baise, iti tur eo i anababatun it isat eo, turobe iti tur hikikirum it tananowar isan, anayabin orot yait me ebifufubiy naatu orot yait ai ro’on rab ekibikib, hairi nuhih fot hima tebowabow anayabin hairi boro nowah nowah hinafaramih hinabow.
11 Bí àwa ti fún irúgbìn ohun ti ẹ̀mí sínú ọkàn yín, ohun ńlá ha ni bí àwa ó ba ká ohun ti yín tí ṣe ti ara?
11 Ayubit ana ub gewasin kwa wanawanamaim atatanum isan, kwa biyane sawar baibaisi isan ana bifefeyani, kwanotanot i ra’at kwanekwan?
12 Bí àwọn ẹlòmíràn bá ní ẹ̀tọ́ tí ìrànlọ́wọ́ sì wá láti ọ̀dọ̀ yín, àwa ha kọ́ ni ó tọ́ sí jù?
12 Orot afa tebowabow baibais kwabitih na’atube, aki auman karam boro baibais kwaniti.
13 Ǹjẹ́ ó yé e yín pé Ọlọ́run sọ fún àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ nínú tẹmpili pé kí wọ́n mú oúnjẹ tàbí àwọn ẹ̀bùn tí wọ́n mú wá fún òun, láti fi ṣe ìtọ́jú ara wọn? Àti àwọn tí ń dúró tí pẹpẹ wọn a máa ṣe àjọpín pẹ̀lú pẹpẹ.
13 Kwaso’ob orot iyab Tafaror Bar gagamin wanawanan tebowabow hai bay i Tafaror Bar ana siwarane tebaib, naatu orot iyab gem kakafiyinamaim sibor te’aa auman i gem kakafiyin tafanamaim sibor turin tebaib.
14 Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni Olúwa ti fi àṣẹ lélẹ̀ pé, àwọn tí ń wàásù ìyìnrere kí wọn sì máa jẹ́ nípa ìyìnrere.
14 Ef i ta’imon, Regah ana obaiyunen turamaim na’atube eo, “Sabuw iyab tur gewasin tibibinan hai ma gewas isan baibais kafai i nati’ine nan hinab.”
15 Síbẹ̀síbẹ̀ n kò ì tí ì lo irú àwọn ẹ̀tọ́ wọ̀nyí rí. Bẹ́ẹ̀ ni èmi kò sì kọ ìwé yìí láti fi sọ fún un yín pé, mo fẹ́ bẹ̀rẹ̀ sí í gbà irú nǹkan bẹ̀ ẹ́ lọ́wọ́ yín. Kí a sọ òtítọ́, ó sàn fún mi láti kú sínú ebi ju pé kí n sọ ògo tí mo ní láti wàásù nù.
15 Baise ayu iti fair men kafa’imo ta abutubun, naatu iti fef akikirum i men sawar ta kwa biyane bain isan anot ao’omih! Baise mi’itube ata morob, men basit ata ma sabuw afa au ora’ara’at tur hitabotabir yabin en tamatar.
16 Nítorí pé bí mo ti ń wàásù ìyìnrere, kì í ṣe ohun tí mo lè máa ṣògo lè. Èmi kò tilẹ̀ le è ṣe é ní, kí a tilẹ̀ sọ pé mo fẹ́ kọ̀ ọ́ sílẹ̀. Ègbé ni fún mi tí mo bá kọ̀ láti wàásù ìyìnrere.
16 Tur gewasin abibinan isan men imaim au fair anab anao ra’ara’atamih, nati bowabow i ayu hiyunu abowabow. Naatu tur gewasin men ana bibinan kakafin anababatun boro isou namatar!
17 Tó bá jẹ́ pé mò ń wàásù tinútinú mi, mo ní èrè kan, ṣùgbọ́n tí ń kò bá ṣe tinútinú mi, a ti fi iṣẹ́ ìríjú lé mi lọ́wọ́.
17 Anayabin iti bowabow au kokomaim ata rubin ata bowabow baiyan boro atab, baise God ana kokomaim ayu rubinu ana bowabow itu abowabow.
18 Ní irú ipò báyìí, kín ni ẹ rò pé yóò jẹ èrè mi ni láti jẹ́? Èrè mi ní àgbàyanu ayọ̀ tí mo ń rí gbà nípa ìwàásù ìyìnrere láìgba owó lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni, láìbéèrè ẹ̀tọ́ mi lọ́wọ́ ẹnikẹ́ni.
18 Imih baiyan isan men anao, baise veya kebor abaibimaim Tur gewasin ana binan, ana baiyan en. Naatu men ayu binanuyan anarouw kwa anifefeyanimih.
19 Bí mo ti jẹ́ òmìnira tí ń kò sì darapọ̀ mọ́ ẹnikẹ́ni, mo sọ ara mi di ẹrú lọ́dọ̀ gbogbo ènìyàn, láti lè jèrè ọ̀pọ̀lọpọ̀ sí i.
19 Ayu i men yait ta ana fafatum wanawanan ama’ama’amih. Baise ayu taiyuwu ayara’iyu sabuw etei hai akir wairafin amatar, saise sabuw moumurih ananawiyih Keriso hinaso’ob.
20 Nígbà tí mó wà lọ́dọ̀ àwọn Júù, mo dàbí ọ̀kan nínú wọn, kí wọn ba à lè tẹ́tí sí ìwàásù ìyìnrere mi àti ki n le jèrè wọn fún Kristi. Nígbà tí mo bá wà láàrín àwọn tó wà lábẹ́ òfin èmi kì í bá wọn jiyàn rárá (bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé èmi kò sí lábẹ́ òfin), kí èmi lè jèrè àwọn ti ń bẹ lábẹ́ òfin.
20 Jew sabuw wanawanahimaim ayu Jew orot amamatar, saise ana buwih, sabuw iyab ofafar babanamaim tema’am ayu imaim ama’am, (baise ofafar men abi’ufunun) saise sabuw ofafarane ana botaitih.
21 Nígbà tí mo bá wà láàrín àwọn tí kò sí lábẹ́ òfin, èmi náà yóò dàbí ẹni tí kò sí lábẹ́ òfin (èmi kì í ṣe aláìlófin sí Ọlọ́run, ṣùgbọ́n èmí ń bẹ lábẹ́ òfin Kristi), kí èmi le jèrè àwọn tí kò sí lábẹ́ òfin.
21 Sabuw iyab ofafar ufunane tema’am, ayu i hai ma’abe bairi ama’am, (iti na’atube asisinaf i men God ana ofafar ufunane ama’am baise Keriso ana ofafar wanawanan ama’am) saise sabuw ofafar ufunane tema’am abow Keriso wanawanan tirur.
22 Nígbà tí mo bá wà láàrín àwọn aláìlera, èmi náà yóò di aláìlera, kí èmi lé jèrè àwọn aláìlera. Mo di ohun gbogbo fún gbogbo ènìyàn, kí èmi ba à lè gba díẹ̀ là lábẹ́ bí ó ti wù kí ó rí.
22 Sabuw ririmih wanawanah ayu ariririm, saise ririmih anabuwih. Sawar ta ta etei hai naniyan amatar sabuw etei isah abotawiy, saise ef menatanane nabobotawiy sabuw turin aniyawas.
23 Èmi sì ń ṣe ohun gbogbo nítorí ti ìyìnrere, kí èmi kí ó lè jẹ́ alábápín nínú rẹ̀ pẹ̀lú yín.
23 Ayu iti asisinaf anayabin Tur gewasin isan, saise tur gewasin ana baigegewasin turin anab.
24 Ẹ̀yin kò mọ̀ pé, olúkúlùkù ẹni tí ó ní ipa nínú eré ìje ni ó máa ń sáré, ṣùgbọ́n ẹnìkan ṣoṣo ni ń gba ipò ẹ̀bùn tí ó ga jù. Nítorí náà, ẹ sá eré ìje yín kí ẹ ba à le borí.
24 Nunuwayah kwana’itih, sabuw etei tinununuw baise orot ta’imon boro nanunuw so’ar ana siwar nab. Imih yuwa kwana’asfofor kwananunuw saise siwar kwanab.
25 Gbogbo ẹni tí ó ń sáré ìje a máa lọ nínú ìsẹ́ra-ẹni tí ó lágbára. Wọ́n ń ṣe èyí láti gba adé ìdíbàjẹ́. Ṣùgbọ́n àwa ń sá eré ìje tiwa láti fi gba adé ọ̀run àìdíbàjẹ́ láéláé.
25 Fafowayah etei bai’a’it fokarin wanawanan hinarun naatu hinan hai siwar hinab, nati siwar i boro natafofor, baise it abisa tasisinaf i ata siwar wanatowan ema’am bain isan tabowabow.
26 Nítorí náà, mo ń sá eré ìje lọ sójú àmì, kì í ṣe bí ẹni ti kò dá lójú. Mò ń jà kí n lè borí, kì í ṣe bí ẹni tí ń bá afẹ́fẹ́ jà.
26 Isan imih ayu men orot afa tinununuw kwanekwan na’atube anununuwamih baise au etawanamaim anununuw, na’atube au baiyow i men asir aroberob kwanekwan, orot baiyowayan eroberob kwanekwan na’atube.
27 Ṣùgbọ́n èmi ń kó ara mi ní ìjánu, mo sì ń mú un wá sí abẹ́ ìtẹríba, pé lẹ́yìn tí mo ti wàásù fún àwọn ẹlòmíràn, nítorí ohunkóhun, kí èmi fún rara mi má ṣe di ẹni ìtanù fún ẹ̀bùn náà.
27 Baise ayu biyou arab baikwatutunen fokarin aitin ayamutufur. Imaibo tur sabuw afa isah abibinan saise etei nunuw wanawanan hinarun asir ayu boro hinabotaitu siwar baina’e anama.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Coríntios 9, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.