1 Coríntios 7
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Ní báyìí, nítorí àwọn ohun tí ẹ ṣe kọ̀wé: Ó dára fún ọkùnrin kí ó máa ṣe ni ìdàpọ̀ pẹ̀lú obìnrin.
1 Boun i kwa fefemaim abisa isan kwakikirum i anao kwananowar. Orot yait tabina’e asir ema’am i gewasin maiyow.
2 Ṣùgbọ́n nítorí àgbèrè pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ gẹ́ẹ́ kí ọkùnrin kọ̀ọ̀kan gbéyàwó tirẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni kí obìnrin kọ̀ọ̀kan ní ọkọ tirẹ̀.
2 Baise anayabin baiwa’an kwanekwan ana naniyan i ra’at, imih orot babin iyab tabina’e tema’am mi’itube hitatabin, saise i a’awah bairi’ika hitama.
3 Kí ọkùnrin kí ó fi gbogbo ẹ̀tọ́ ìyàwó rẹ̀ fún ún, kí ìyàwó fi gbogbo ẹ̀tọ́ ọkọ fún ọkọ rẹ̀.
3 Naatu orot ana kok abisa aawan biyanamaim tasinaf tiyasisir na’atube babin ana kok abisa aawan biyanamaim tiyasisir.
4 Aya kò láṣẹ lórí ara rẹ̀ mọ́, ara rẹ̀ ti di ti ọkọ rẹ̀. Bákan náà ni ọkùnrin tí ó gbéyàwó kò ní àṣẹ lórí ara rẹ̀ mọ́, ara rẹ̀ ti di ti ìyàwó rẹ̀.
4 Babin biyan men i akisin nowanamih, baise orot nowan, na’atube orot biyan men i akisin nowanamih, baise babin nowan, na’atube orot biyan men akisin nakaif, baise babin nakaif, naatu babin biyan men akisin nakaif baise orot nakaif.
5 Nítorí náà, ẹ má ṣe fi àwọn ẹ̀tọ́ tọkọtaya wọ̀nyí dun ara yín, bí kò ṣe nípa ìfìmọ̀ṣọ̀kan, kí ẹ̀yin lè fi ara yín fún àwẹ̀ àti àdúrà, kí ẹ̀yin sì tún jùmọ̀ pàdé, lẹ́yìn ìgbà náà, wọ́n gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ ara wọn kí Satani má ba à dán wọn wò nítorí àìlèmáradúró wọn.
5 Imih orot aawan hairi inumih nakokok babin men nakwahir, na’atube babin aawan hairi iumih nakokok orot men nakwahir, baise veya afa hairi hinibasit mar kafai asir hinama, saise nati veya i yoyoban hinitin. Imaibo veya ta naniyah nakokok na’at aawan hairi hina’in saise biyah ana naniyan na’in bainub, asir boro Satan imaim nan narun routobon nitih.
6 Mo sọ èyí fún un yín bí ìmọ̀ràn ní kì í ṣe bí àṣẹ.
6 Iti i ayu au not kwa au’uwi, baise men nati na’atube sinaf isan abiyunimih.
7 Ó wù mí kí olúkúlùkù dàbí èmi, ṣùgbọ́n gbogbo ènìyàn kò le jẹ́ bákan náà, Ọlọ́run fún olúkúlùkù ènìyàn ní ẹ̀bùn tirẹ̀, ọ̀kan bí irú èyí àti èkejì bí irú òmíràn.
7 Ayu au kok kwa etei mi’itube ayu’ube kwatama, baise orot ta’ita’imon ata usar etei God faramit, orot ta i ana usar ta God itin, na’atube orot ta ibo ana usar ta God itin.
8 Nítorí náà, mo wí fún àwọn àpọ́n àti opó pé, ó sàn kí wọ́n kúkú wà gẹ́gẹ́ bí èmi tí wà.
8 Baise kwa tabin ati’at, naatu kwafukwafuriy, katukatuwiy, kwa auman au’uwi, gewasin tabin en asir kwatama, ayu ama’ama’abe.
9 Ṣùgbọ́n bí wọ́n kò bá lè mú ara dúró, kí wọ́n gbéyàwó tàbí kí wọ́n fẹ́ ọkọ, nítorí pé ó sàn láti gbéyàwó jù láti ṣe ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ lọ.
9 Baise a naniyan nakukura’ara’ah na’at, gewasin kwanatabin, anayabin tabin i gewasin, men basit baiwa’an isan itanot dogor wairafabe ta’arah mar etei.
10 Àwọn ti ó ti gbéyàwó àti àwọn tí ó lọ́kọ, ni mo fẹ́ pa á láṣẹ fún kì í ṣe láti ọ̀dọ̀ mi ṣùgbọ́n láti ọ̀dọ̀ Olúwa: “Obìnrin kò gbọdọ̀ kọ́ fi ọkọ rẹ̀ sílẹ̀.”
10 Kwa toutabin sabuw obaiyunen tur iti abit, men ayu, baise Regah ana obaiyunen tur, babin men aaw orot inihamiy.
11 Ṣùgbọ́n tí ó bá fi ọkọ rẹ̀ sílẹ̀; jẹ́ kí ó wà láìní ọkọ mọ́, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, kí ó bá ọkọ rẹ̀ làjà, kí ọkọ kí ó má ṣe aya rẹ̀ sílẹ̀.
11 Baise babin yait aawan orot nabihamiy na’at, gewasin nati babin men natabin asire nama, naatu nakokok na’at namatabir maiye aawan hairi hitounuw hinama. Naatu orot men aaw inakwahir.
12 Mo fẹ́ fi àwọn ìmọ̀ràn kan kún ún fún un yín, kì í ṣe àṣẹ láti ọ̀dọ̀ Olúwa. Bí arákùnrin bá fẹ́ aya tí kò gbàgbọ́, tí aya náà sá á fẹ́ dúró tí ọkọ náà, ọkọ náà tí í ṣe onígbàgbọ́ kò gbọdọ̀ kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
12 Baise kwa afa isa ayu akisu au not iti, men Regah ana not. Orot yait babin men baitumatumayan ebi’awan naatu babin ana kok i orot hairi ma’amih, orot men babin nakwahir.
13 Tí ó bá sì jẹ́ obìnrin ló fẹ́ ọkọ tí kò gbàgbọ́, ṣùgbọ́n tí ọkọ náà ń fẹ́ kí obìnrin yìí dúró tí òun, aya náà kò gbọdọ̀ kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
13 Naatu babin yait orot men baitumatumayan ebi’awan orot ana kok i babin hairi ma’amih, babin men orot nakwahir.
14 Nítorí pé ó ṣe é ṣe kí a lè mú ọkọ tí kò gba Kristi gbọ́ súnmọ́ Ọlọ́run nípa aya tí í ṣe onígbàgbọ́, a sì le mú ìyàwó tí kò gba Kristi gbọ́ súnmọ́ Ọlọ́run nípa ọkọ tí í ṣe onígbàgbọ́. Bí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀, àwọn ọmọ wọn yóò jẹ́ aláìmọ́. Ṣùgbọ́n bí wọn kò bá kọ ara wọn sílẹ̀, ó ṣe é ṣe kí àwọn ọmọ wọn di mímọ́.
14 Anayabin orot ana baitumatumamaim babin kusouw na kakafiyin matar, na’atube orot ana baitumatumamaim babin kusouw na kakafiyin matar, asire natunatuh boro gubagub auman hitama, baise boun natunatuh i hina kakafiyih himatar.
15 Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin tí i ṣe aláìgbàgbọ́ náà bá fẹ́ láti lọ, jẹ́ kí ó máa lọ. Arákùnrin tàbí arábìnrin náà kò sí lábẹ́ ìdè mọ́; Ọlọ́run ti pè wá láti gbé ní àlàáfíà.
15 Baise orot baitumatum atin ekokok aawan kwahirinamih, kwaihamiy ekwahir, anayabin hairi hai tabin men hifatum. God ana kok it i tufuwamaim tanama.
16 Báwo ni ẹ̀yin aya ṣe le mọ̀ pé bóyá ẹ̀yin ni yóò gba ọkọ yín là? Bákan náà ni a lè wí nípa ọkọ tí í ṣe onígbàgbọ́ pé, kò sí ìdánilójú pé aya aláìgbàgbọ́ le yípadà láti di onígbàgbọ́ nípa dídúró ti ọkọ.
16 O babin aaw baibaisin na baitumatumayan matar isan ana ef boro mi’itube inaso’ob gewas? Naatu o orot, aaw baibaisin na baitumatumayan matar isan ana ef boro mi’itube inaso’ob gewas?
17 Ṣùgbọ́n ẹ jẹ́ kí olúkúlùkù máa gbé ìgbé ayé tí Ọlọ́run ń fẹ́ yín fún, àti nínú èyí tí Olúwa pè é sí. Ìlànà àti òfin mi fún gbogbo ìjọ ni èyí.
17 Ef ta’imon i iti, orot babin ta’ita’imon ana yawas abisa Regah bitin na’atube imaim nama. Yawas wantoro’ot mi’itube tama’ama God ea’afit na’atube tanama. Iti i ayu au obaiyunen tur ekaleisia wanawanan areremor i abi’obaiyih.
18 Ǹjẹ́ ọkùnrin kan ha ti kọlà nígbà tí a pè é? Kí ó má sì ṣe di aláìkọlà. Ǹjẹ́ ọkùnrin kan ha ti kọlà nígbà tí a pè é? Kí ó ma ṣe kọlà.
18 O yait a’ar mo’on hi’afuw ima’am ana veya God ea’afi, men a fit inibunwa’ir, naatu orot yait ana ar mo’on afuwina’e ma’am ana veya God eafi’af, men ana ar mo’on afuwinamih nanot.
19 Ìkọlà kò jẹ́ nǹkan àti àìkọlà kò jẹ́ nǹkan, bí kò ṣe pípa òfin Ọlọ́run mọ́.
19 Anayabin orot ana ar mo’on afu’afuw, o afuwina’e nati i yabin en, baise ana’an gagamin i God ana obaiyunen tur tanabosiyasiyar.
20 Ó yẹ kí ẹnìkọ̀ọ̀kan máa ṣe iṣẹ́ tí ó ń ṣe tẹ́lẹ̀, kí Ọlọ́run tó pé é sínú ìgbàgbọ́ nínú Kristi.
20 Orot etei mi’itube kwama’am ana veya God ea’afi i na’atube kwanama.
21 Ǹjẹ́ ẹrú ni ọ́ bí nígbà ti a pè ọ́? Má ṣe kà á sí. Ṣùgbọ́n tí ìwọ bá le di òmìnira, kúkú ṣe èyí nì.
21 O yait bai’akir ana yawasamaim ima’am ana veya God ea’afi, men nati isan iniyababan, baise a veya kebor inabaib na’at nati bai’akir ana fafatumane kurufami kutit.
22 Tí ó bá jẹ́ ẹrú, ti Olúwa sì pé ọ, rántí pé Kristi ti sọ ọ́ di òmìnira kúrò lọ́wọ́ agbára búburú ti ẹ̀ṣẹ̀. Tí ó bá sì ti pé ọ̀ nítòótọ́ tí ó sì ti di òmìnira, ó ti di ẹrú Kristi.
22 Anayabin orot yait akir ana bowabowamaim ma’am Regah eaf titit, i Regah ana rufamen orot, na’atube orot yait roufamenamaim ma’am Keriso eaf titit, nati orot i Keriso ana akir wairafin.
23 A sì ti rà yín ní iye kan, nítorí náà ẹ má ṣe di ẹrú ènìyàn.
23 Kwa i sawar ta baiyan gagaminamaim God tubuni kwatit, imih men kwanan orot ta isan kwani’akiramih.
24 Ará, jẹ́ kí olúkúlùkù ènìyàn, nínú èyí tí a pè é, kí ó dúró nínú ọ̀kan náà pẹ̀lú Ọlọ́run.
24 Taitu, kwa ta’ita’imon ama mi’itube kwama’am God e’afi kwana baitumatumayah kwamamatar na’atube kwanama.
25 Ṣùgbọ́n nípa ti àwọn wúńdíá, èmi kò ní àṣẹ kankan láti ọ̀dọ̀ Olúwa, ṣùgbọ́n mo wí fún yín ní ìdájọ́ bí ẹni tí ó rí àánú Olúwa gbà láti jẹ́ olódodo.
25 Naatu kwa baibitar biya numih, kwa isa ayu men Regah biyanane tur ta abaimih, baise Regah ana kabeberamaim ayu not iti bitu ana’o i kwanitumatum.
26 Nítorí náà mo rò pé èyí dára nítorí wàhálà ìsinsin yìí, èyí nì ni pé o dára fún ènìyàn kí ó wà bí o ṣe wà.
26 Mar iti boun yawas i fokar, imih ayu anotanot ana gewasin kwa mi’itube kwama’am i na’atube kwanama.
27 Ǹjẹ́ ó ti ṣe ẹlẹ́rìí láti fẹ́ ìyàwó. Ẹ má ṣe kọ ara yín sílẹ̀, nítorí èyí tí mo wí yìí. Ṣùgbọ́n tí o kò bá sì tí ìgbéyàwó, tàbí fẹ́ ọkọ, má ṣe sáré láti ṣe bẹ́ẹ̀ lákokò yìí.
27 O toutabin na’at men babin kwahirinamih ana ef inanuwet, naatu o tabina’e kuma’am men tabinamih babin inanuwet.
28 Ṣùgbọ́n bí ìwọ bá gbé ìyàwó ìwọ kò dẹ́ṣẹ̀, bí a bá gbé wúńdíá ní ìyàwó òun kò dẹ́ṣẹ̀. Ṣùgbọ́n irú àwọn tí ó bá gbé ìyàwó yóò dojúkọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ wàhálà nípa ti ara, ṣùgbọ́n èmi fẹ́ dá a yín sí.
28 Baise inatatabin na’at nati i men bowabow kakafin kusisinaf, naatu babitai tatabin auman i men bowabow kakafin esisinaf, baise kwa iyab kwatatabin yababan boro moumurih maiyow kouh kwanayen, imih tarafafari isan tur iti ao.
29 Òun ti mo ń wí ará, ni pé kúkúrú ni àkókò, láti ìsinsin yìí lọ, ẹni tí ó ni aya kí ó dàbí ẹni tí kò ní rí;
29 Taitu, abisa ao yabin i iti, mar i na kabom, imih boun it ata veya’amaim orot iyab toutabin tema’am hinimonok Regah isan hinabow.
30 àwọn tí ń sọkún, bí ẹni pé wọn kò sọkún rí, àti àwọn tí ń yọ̀ bí ẹni pé wọn kò yọ̀ rí, àti àwọn tí ń rà bí ẹni pé wọn kò ní rí,
30 Sabuw iyab terererey, hai itinin men yababanabe hinama’amih, sabuw iyab tibiyasisir hai itinin men yasisirabe hinama’amih. Naatu sabuw iyab guguw wairafih hai itinin i guguw enabe hinama.
31 àti àwọn tó ń lo ohun ayé yìí, bí ẹni tí kò ṣe àṣejù nínú wọn: nítorí ìgbà ayé yìí ń kọjá lọ.
31 Kwa iyab iti tafaram ana sawar moumurih na’in kwabowabow men sawar anot awan nakaratan, anayabin iti tafaram naatu sawar etei boro nan nasawar.
32 Nínú gbogbo nǹkan tí ẹ bá ń ṣe ni mo tí fẹ́ kí ẹ sọ ara yín di òmìnira lọ́wọ́ àníyàn. Ọkùnrin tí kò ní ìyàwó le lo àkókò rẹ̀ láti fi ṣiṣẹ́ fún Olúwa, yóò sì má ronú bí ó ti ṣe le tẹ́ Olúwa lọ́rùn.
32 Ayu akokok kwa etei yababan fatumi kwama’am kwanarufami kwanatit. Orot tabina’e ema’am ana not etei Regah ana bowabow isan ebitin, ekokok nabow Regah niyasisir.
33 Ṣùgbọ́n ọkùnrin tí ó bá tí ṣe ìgbéyàwó kò le ṣe bẹ́ẹ̀, nítorí ó ní láti ronú àwọn nǹkan rẹ̀ nínú ayé yìí àti bí ó ti ṣe le tẹ́ aya rẹ̀ lọ́rùn,
33 Baise toutabin orot i tafaram ana bowabow isan enotanot kwanekwan, anayabin i ekokok nabow aawan niyasisir.
34 dájúdájú, ìfẹ́ rẹ̀ pín sí ọ̀nà méjì. Bákan náà ló rí fún obìnrin tí a gbé ní ìyàwó àti wúńdíá. Obìnrin tí kò bá tí ì délé ọkọ a máa tọ́jú ohun tí ṣe ti Olúwa, kí òun lè jẹ́ mímọ́ ní ara àti ní ẹ̀mí. Ṣùgbọ́n ọmọbìnrin tí a bá ti gbé níyàwó, a máa ṣe ìtọ́jú ohun tí ṣe ti ayé, bí yóò ti ṣe le tẹ́ ọkọ rẹ̀ lọ́rùn.
34 Imih i ana not kusib ef rou’ab himatar, ef ta’imon nati na’atube, babin tabina’e ema’am o babitai biyan numin, ana not tutufin etei i Regah ana bowabow akisin isan enotanot. Baise toutabin babin i tafaram ana bowabow isan enotanot kwanekwan, anayabin i ekokok nabow aawan orot niyasisir.
35 Mo ń sọ èyí fún àǹfààní ara yín kì í ṣe láti dá yín lẹ́kun ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin lè gbé ní ọ̀nà tí ó tọ́ kí ẹ sì lè máa sin Olúwa láìsí ìyapa ọkàn.
35 Ayu iti ao anayabin akokok kwa anibais, i men ao’ofafari, baise akokok ef gewasin kwasinaf a yabow Regah isan i wan kwanayai kwanabow.
36 Ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni bá rò pé òun kò ṣe ohun tí ó yẹ sí wúńdíá rẹ̀ ti ìpòùngbẹ rẹ si pọ si, bí ó bá sí tọ́ bẹ́ẹ̀, jẹ́ kí ó ṣe bí ó tí fẹ́, òun kò dẹ́ṣẹ̀, jẹ́ kí wọn gbé ìyàwó.
36 Monok babitai hairi hai rum hio, naatu monok naniyan i ekukura’ara’ah babitai isan naatu kwamur auman i erara’at ekokok natabin, karam hinatabin men bowabow kakafin.
37 Ṣùgbọ́n ẹni tí ó dúró ṣinṣin ni ọkàn rẹ̀, tí kò ní àìgbọdọ̀ má ṣe, ṣùgbọ́n tí ó ní agbára lórí ìfẹ́ ara rẹ̀, tí ó sì ti pinnu ní ọkàn rẹ̀ pé, òun ó pa wúńdíá ọmọbìnrin òun mọ́, yóò ṣe rere.
37 Baise orot yait i taiyuwin ana notamaim tabin men ekokok men yait na’okikin, i karam taiyuwin ana naniyan imurub ema’am karam tabina’e nama, iti orot i ef gewasin esisinaf.
38 Bẹ́ẹ̀ sì ní ẹni tí ó fi wúńdíá ọmọbìnrin fún ni ní ìgbéyàwó, ó ṣe rere; ṣùgbọ́n ẹni tí kò fi fún ni ní ìgbéyàwó ṣe rere jùlọ.
38 Imih orot yait etatabin i gewasin, baise orot yait tabina’e ema’am i gewasin anababatun.
39 A fi òfin dé obìnrin níwọ̀n ìgbà tí òun pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ wà láààyè, bí ọkọ rẹ̀ bá kú, ó ní òmìnira láti ṣe ìgbéyàwó pẹ̀lú ọkùnrin mìíràn, tí ó bá wù ú ó sì gbọdọ̀ jẹ́ ti Olúwa.
39 Orot yawasin ema’am ana veya babin i aawan biyanamaim hifatum ema’am, baise orot emomorob ana veya babin i orot biyanamaim hirufam tit, orot ta i ana kokomaim boro ni’awan, baise nati orot i Regah ana kou’ayomaim ema’am ni’awan.
40 Ṣùgbọ́n nínú èrò tèmi obìnrin náà yóò ní ayọ̀ púpọ̀, tí kò bá ṣe ìgbéyàwó mìíràn mọ́. Mo sì rò pé mo ń fún un yín ní ìmọ̀ràn láti ọ̀dọ̀ Ẹ̀mí Ọlọ́run nígbà tí mo ń sọ nǹkan wọ̀nyí.
40 Baise anotanot tabina’e tama’am na’at i boro tiyasisir gagamin maiyow. Ayu anotanot ayu auman God Anunin targabuwu ama’am.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Coríntios 7, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.