1 Coríntios 16
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs NTLH
1 Ǹjẹ́ ní ti ìdáwó fún àwọn ènìyàn mímọ́, bí mo tí wí fún àwọn ìjọ Galatia, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ní kí ẹ ṣe.
1 Agora vou tratar do dinheiro para ajudar o povo de Deus da Judeia. Façam o que eu disse às igrejas da província da Galácia.
2 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní ọ̀sẹ̀, kí olúkúlùkù yín fi sínú ìṣúra lọ́dọ̀ ara rẹ̀ ni apá kan, gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run ti ṣe rere fún ún, ki ó má ṣe si ìkójọ nígbà tí mo bá dé.
2 Todos os domingos cada um de vocês separe e guarde algum dinheiro, de acordo com o que cada um ganhou. Assim não haverá necessidade de recolher ofertas quando eu chegar.
3 Àti nígbà ti mo bá dé, àwọn ẹni tí ẹ bá yàn, àwọn ni èmi ó rán láti mú ẹ̀bùn yín gòkè lọ si Jerusalẹmu.
3 Depois que chegar, eu enviarei, com cartas de apresentação, aqueles que vocês escolherem para levarem a oferta até Jerusalém.
4 Bí ó bá sì yẹ kí èmí lọ pẹ̀lú, wọn ó sì bá mi lọ.
4 Se for conveniente que eu também vá, eles farão a viagem comigo.
5 Ṣùgbọ́n èmi yóò tọ̀ yin wá, nígbà tí èmí bá ti kọjá láàrín Makedonia: nítorí èmi yóò kọjá láàrín Makedonia.
5 Eu visitarei vocês depois que tiver passado pela província da Macedônia, pois vou passar por lá.
6 Bóyá èmi ó sì dúró pẹ̀lú yín, tàbí kí n tilẹ̀ lo àkókò òtútù, ki ẹ̀yin lé sìn mí ni ọ̀nà àjò mí, níbikíbi tí mo bá ń lọ.
6 Pode ser que eu fique algum tempo com vocês, talvez todo o inverno, e assim vocês poderão me ajudar a continuar a minha viagem para onde quer que eu for.
7 Nítorí èmi kò fẹ́ kan ri yín kí èmi sì ṣe bẹ́ẹ̀ kọjá lọ; nítorí èmi ń retí àti dúró lọ́dọ̀ yín díẹ̀, bí Olúwa bá fẹ́.
7 Pois eu não quero ver vocês apenas de passagem. Se o Senhor permitir, espero ficar bastante tempo com vocês.
8 Ṣùgbọ́n èmi yóò dúró ni Efesu títí dí Pentikosti.
8 Resolvi ficar aqui em Éfeso até o dia de Pentecostes .
9 Nítorí pé ìlẹ̀kùn ńlá láti ṣe iṣẹ́ gidi ṣí sílẹ̀ fún mí, ọ̀pọ̀lọpọ̀ sì ni àwọn ọ̀tá tí ń bẹ.
9 Pois encontrei aqui ótimas oportunidades para um grande e proveitoso trabalho, embora muita gente esteja contra mim.
10 Ǹjẹ́ bí Timotiu bá dé, ẹ jẹ́ kí ó wà lọ́dọ̀ yín láìbẹ̀rù, nítorí òun ń ṣé iṣẹ́ Olúwa, bí èmi pẹ̀lú ti ń ṣe.
10 Se Timóteo chegar aí, façam tudo para que ele se sinta bem entre vocês; pois, assim como eu, ele também está trabalhando para o Senhor.
11 Nítorí náà kí ẹnikẹ́ni má ṣe kẹ́gàn rẹ̀. Ṣùgbọ́n ẹ sín ín jáde lọ́nà àjò ni àlàáfíà, kí òun lè tọ̀ mí wá; nítorí tí èmí ń fi ojú sí ọ̀nà fún wíwá rẹ̀ pẹ̀lú àwọn arákùnrin.
11 Não deixem que ninguém o despreze. Pelo contrário, vocês devem ajudá-lo a continuar a sua viagem em paz, a fim de que ele volte para cá. Pois estou esperando que ele volte junto com os outros irmãos.
12 Ṣùgbọ́n ní ti Apollo arákùnrin wa, mo bẹ̀ ẹ́ púpọ̀ láti tọ̀ yín wá pẹ̀lú àwọn arákùnrin, ṣùgbọ́n kì í ṣe ìfẹ́ rẹ̀ rárá láti wà nísinsin yìí, ṣùgbọ́n òun yóò wá nígbà tí ààyè bá ṣí sílẹ̀ fún un.
12 Quanto ao irmão Apolo, tenho recomendado muitas vezes que vá visitar vocês com os outros irmãos, mas ele acha que não deve ir agora. Ele irá na primeira oportunidade.
13 Ẹ máa ṣọ́ra, ẹ dúró ṣinṣin nínú ìgbàgbọ́, ẹ ṣe bi ọkùnrin tí ó ní ìgboyà, ẹ jẹ́ alágbára.
13 Estejam alertas, fiquem firmes na fé, sejam corajosos, sejam fortes.
14 Ẹ máa ṣe ohun gbogbo nínú ìfẹ́.
14 Que tudo o que vocês fizerem seja feito com amor.
15 Ǹjẹ́ mo bẹ̀ yín ará, ẹ ṣá mọ ilé Stefana pé, àwọn ni ẹni àkọ́kọ́ tó gba Jesu ní Akaia, àti pé, wọn sì tí fi ará wọn fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ àwọn ènìyàn mímọ́.
15 Vocês conhecem Estéfanas e a família dele. Vocês sabem que eles foram os primeiros cristãos convertidos na província da Acaia e que eles têm se dedicado ao serviço do povo de Deus. Peço a vocês, meus irmãos,
16 Kí ẹ̀yin tẹríba fún irú àwọn báwọ̀nyí, àti fún olúkúlùkù olùbáṣiṣẹ́ pọ̀ pẹ̀lú wa tí ó sì ń ṣe làálàá.
16 que sigam a orientação deles e dos outros que os ajudam e trabalham com eles.
17 Mo láyọ̀ fún wíwá Stefana àti Fortunatu àti Akaiku, nítorí èyí tí ó kù nípá tí yín wọ́n ti fi kún un.
17 Eu estou alegre com a vinda de Estéfanas, de Fortunato e de Acaico, pois eles fizeram o que vocês, por estarem ausentes, não podiam fazer.
18 Nítorí tí wọ́n tu ẹ̀mí mí lára àti tiyín: nítorí náà, ẹ máa gba irú àwọn ti ó rí bẹ́ẹ̀.
18 Eles me animaram muito, e sei que animaram vocês também. Gente como essa merece elogios.
19 Àwọn ìjọ ni Asia kí í yín.
19 As igrejas da província da Ásia mandam saudações. Áquila e a sua esposa Priscila e a igreja que se reúne na casa deles mandam saudações cristãs a vocês.
20 Gbogbo àwọn arákùnrin kí í yín.
20 Todos os irmãos daqui mandam saudações. Cumprimentem uns aos outros com um beijo de irmão.
21 Ìkíni ti èmi Paulu, láti ọwọ́ èmi tìkára mi wá.
21 Escrevo isto com a minha própria mão: Saudações de Paulo.
22 Bí ẹnikẹ́ni kò bá ní ìfẹ́ Jesu Kristi Olúwa, jẹ́ kí ó dì ẹni ìfibú. Máa bọ Olúwa wa!
22 Quem não ama o Senhor, que seja amaldiçoado! “Marana tá” — Vem, nosso Senhor !
23 Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa kí ó wà pẹ̀lú yín!
23 Que a graça do nosso Senhor Jesus esteja com vocês!
24 Ìfẹ́ mi wá pẹ̀lú gbogbo yín nínú Kristi Jesu. Àmín.
24 E que o meu amor esteja com todos vocês, pois estamos unidos com Cristo Jesus!
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Coríntios 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.