1 Coríntios 15
Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI
1 Ǹjẹ́ ará, èmi ń sọ ìyìnrere náà dí mí mọ̀ fún un yín, tí mo ti wàásù fún un yín, èyí tí ẹ̀yin pẹ̀lú ti gbá, nínú èyí tí ẹ̀yin sì dúró.
1 Taitu, boun i akokok tur gewasin abinan kwanowar, imaim yawas kwabai, naatu imaim kwabatabatkikin isan nuhi akukusib.
2 Nípasẹ̀ ìyìnrere yìí ni a fi ń gbà yín là pẹ̀lú, bí ẹ̀yin bá di ọ̀rọ̀ ti mo ti wàásù fún yín mú ṣinṣin. Bí bẹ́ẹ̀ kọ̀, ẹ̀yin kàn gbàgbọ́ lásán.
2 Iti tur gewasinamaim kwa iyawasi, imih tur abinan kwanonowar kwanabubukikin, baise men kwanabubukikin kwa a baitumatum boro nan yabin en namatar.
3 Nítorí èyí tí mo rí gbà ṣáájú ohun gbogbo ní èmi pẹ̀lú ti fi lé e yín lọ́wọ́, bí Kristi ti kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wá gẹ́gẹ́ bí ìwé mímọ́ tí wí.
3 Ayu abisa abaib i kwa isa aya’abun, naatu nati tur ana’an gagamin i iti, Keriso it ata bowabow kakafin isan morob, Bukamaim eo na’atube.
4 Àti pé a sìnkú rẹ̀, àti pé ó jíǹde ní ọjọ́ kẹta gẹ́gẹ́ bí Ìwé Mímọ́ tí wí;
4 Hibai hin hubemaim hiyai, veya tounu ufunamaim misir maiye, Bukamaim eo na’atube.
5 àti pé ó farahàn Peteru, lẹ́yìn èyí, àwọn méjìlá.
5 Peter isan irerereb, imaibo tur abarayah nah 12 isah irerereb.
6 Lẹ́yìn èyí, ó farahàn àwọn ará tí o jú ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta (500) lọ lẹ́ẹ̀kan náà; ọ̀pọ̀ nínú wọn wà títí fi di ìsinsin yìí, ṣùgbọ́n àwọn díẹ̀ ti sùn.
6 Nati ufunamaim veya ta’imon wanawanan ana bai’ufununayah etei 500 tafanamaim auman isah irerereb, moumurih na’in i boun yawasih tema’am baise afa i himorob.
7 Lẹ́yìn èyí ni ó farahan Jakọbu; lẹ́yìn náà fún gbogbo àwọn aposteli.
7 Nati ufunamaim James isan irerereb, imaibo ana tur abarayah etei isah irerereb.
8 Àti níkẹyìn gbogbo wọn ó farahàn mí pẹ̀lú, bí ẹni tí a bí ṣáájú àkókò rẹ̀.
8 Uftoro’ot ayu atufuw kokobeya na’atube ama’am isou irerereb.
9 Nítorí èmi ni ẹni tí ó kéré jùlọ nínú àwọn aposteli, èmi ẹni tí kò yẹ láti pè ní aposteli, nítorí tí mo ṣe inúnibíni sí ìjọ ènìyàn Ọlọ́run.
9 Ayu i tur abarayah etei babahimaim imih ayu i men boro tur abarayan hinarouw hinao, anayabin God ana ekaleisia ai nununih arouw ai’a’akirih.
10 Ṣùgbọ́n nípa oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run mo rí bí mo ti rí: oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀ tí a fi fún mi kò sì jẹ́ asán; ṣùgbọ́n mó ṣiṣẹ́ lọ́pọ̀lọ́pọ̀ jú gbogbo wọn lọ, ṣùgbọ́n kì í ṣe èmi, bí kò ṣe oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run tí ó wà pẹ̀lú mi.
10 Baise God ana manaw ana kabeberamaim ayu tur abarayan amatar, naatu manaw kabeber ayu bitu i men yabin en, baise bowabow gagamin na’in abow, tur abarayah etei ana tabirih, men ayu au fairamaim abowabowamih, baise God ana manaw ana kabeber ayu wanawana’umaim ma ebowabow.
11 Nítorí náà ìbá à ṣe èmí tàbí àwọn ni, èyí ní àwa wàásù, èyí ní ẹ̀yin sì gbàgbọ́.
11 Isan imih i tibibinan naatu ayu abibinan ana itinin i men ta’amih, baise ana’an gagamin i abisa abibinan i kwa kwaitumatum.
12 Ǹjẹ́ bí a bá wàásù Kristi pé ó tí jíǹde kúrò nínú òkú, èéha tí ṣe tí àwọn mìíràn nínú yín fi wí pé, àjíǹde òkú kò sí.
12 Boun aki abibinan ai tur i Keriso morobone mimisir isan ao’o, baise mi’itube’emih kwa afa kwao moroboyah boro men hinayawas maiye hinamisir?
13 Ṣùgbọ́n bí àjíǹde òkú kò sí, ǹjẹ́ Kristi kò jíǹde.
13 Morobone misir maiye men nama’am na’at, ana itinin Keriso morobone men misir maiye’emih.
14 Bí Kristi kò bá sì jíǹde, ǹjẹ́ asán ni ìwàásù wà, asán sì ni ìgbàgbọ́ yín pẹ̀lú.
14 Naatu Keriso morobone men tamimisir maiye na’at, aki ai binan i yabin en, naatu kwa Keriso kwabitumitum auman i yabin en.
15 Ṣùgbọ́n jù bẹ́ẹ̀ lọ, a mú wa ni ẹlẹ́rìí èké fún Ọlọ́run; nítorí ti àwa jẹ́rìí Ọlọ́run pé ó jí Kristi dìde kúrò nínú òkú: ẹni tí òun kò jí dìde bí ó bá ṣe pé àwọn òkú kò jíǹde?
15 Naatu murumurubih men hinamimisir maiye na’at, aki i God isan abifufuwen. Anayabin Keriso morobone God baiyawasin arouw ao, naatu moroboyah morobone men hinamimisir maiye na’at, nati ebiturobe, God Keriso morobone men iyawas maiye misirimih.
16 Nítorí pé bi á kò bá jí àwọn òkú dìde, ǹjẹ́ a kò jí Kristi dìde,
16 Morobone misir maiye men nama’am na’at, Keriso morobone men misir maiye.
17 bí a kò bá sì jí Kristi dìde, asán ní ìgbàgbọ́ yín; ẹ̀yin wà nínú ẹ̀ṣẹ̀ yín síbẹ̀.
17 Naatu Keriso morobone men tamimisir na’at, kwa a baitumatum i yabin en, naatu kwa i boro’ika bowabow kakafin tafatumi kwatama’ama.
18 Ǹjẹ́ àwọn pẹ̀lú tí ó sùn nínú Kristi ṣègbé.
18 Naatu iban maiye sabuw iyab Keriso wabinamaim himomorob ana itinin i hikasiy na’atube.
19 Bí ó bá ṣe pé kìkì ayé yìí nìkan ní àwa ní ìrètí nínú Kristi, àwa jásí òtòṣì jùlọ nínú gbogbo ènìyàn.
19 Keriso wanawananamaim yawas tabai nuhit fot tama’am. Baise ata yawas i iti tafaram akisin isan tanama tananotanot na’at. It i tafaram wananwanan ana gonenet sabuw tamatar.
20 Ǹjẹ́ nísinsin yìí Kristi tí jíǹde kúrò nínú òkú, ó sì dí àkọ́bí nínú àwọn tí ó sùn.
20 Baise turobe Keriso i anababatun morobone misir maiye, God ana sabuw iyab himomorob wanawanahimaim Keriso i wan morobone misir.
21 Nítorí ìgbà tí ó jẹ́ pé nípa ènìyàn ní ikú ti wá, nípa ènìyàn ní àjíǹde òkú sì ti wá pẹ̀lú.
21 Anayabin orot ta’imon ana sinafumaim morob matar, imih orot ta’imon ana sinafumaim morobone misir maiye matar.
22 Nítorí bí gbogbo ènìyàn ti kú nínú Adamu, bẹ́ẹ̀ ní a ó sì sọ gbogbo ènìyàn dí alààyè nínú Kristi.
22 Sabuw etei tamomorob, anayabin Adam ana rara, naatu morobone boro tanamisir maiye anayabin Keriso yawasin ema’am.
23 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù ènìyàn ní ipá tirẹ̀: Kristi àkọ́bí; lẹ́yìn èyí àwọn tí ó jẹ́ tí Kristi ni wíwá rẹ̀.
23 Baise morobone tanamimisir maiye, i boro koumutufuren inu’in na’atube hinabusuruf, wantoro’ot boro Keriso namisir, naatu nanan ana veya sabuw iyab Keriso nowan boro hinamisir.
24 Nígbà náà ni òpin yóò dé, nígbà tí ó bá ti fi ìjọba fún Ọlọ́run Baba, nígbà tí ó bá pa gbogbo àṣẹ àti gbogbo ọlá àti agbára run.
24 Imaibo mar yomanin nan natit, tafaram hai bonawiyenenayah, hai aiwob, hai kaifenayah etei hai fair tutufin Keriso nagugurus ufunamaim, aiwob nab Tamah God nitin.
25 Nítorí ti òun gbọdọ̀ ti jẹ ọba kí òun to fi gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀ sí abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.
25 Naatu Keriso i boro ni’aiwob nanan ana rakit sabuw etei nabow nan an babanamaim nawastanen.
26 Ikú ní ọ̀tá ìkẹyìn tí a ó parun.
26 Naatu uftoro’ot i sawar wabin Morob it ata rakit gagamin boro nagurus nitaiy nare.
27 “Nítorí ó ti fi ohun gbogbo sábẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀.” Ṣùgbọ́n nígbà tí ó wí pé, “Ohun gbogbo ni á fi sí abẹ́ rẹ̀,” o dájú pé Ọlọ́run nìkan ṣoṣo ní kò sí ní abẹ́ rẹ̀, Òun ní ó fi ohun gbogbo sí abẹ́ àkóso Kristi.
27 Anayabin Buk Atamaninamaim eo, “Sawar etei boro nabow an babanamaim naya.” Iti tur Sawar etei an babanamaim yara’iyen rouw eo, i rerereb yan, God men i auman bobar eomih, anayabin God sawar etei boro Keriso ana fair babanamaim naya.
28 Nígbà tí a bá sì fi ohun gbogbo sí abẹ́ rẹ̀ tán, nígbà náà ni á ó fi ọmọ tìkára rẹ̀ pẹ̀lú sábẹ́ ẹni tí ó fi ohun gbogbo sí abẹ́ rẹ̀, kí Ọlọ́run lè jásí ohun gbogbo nínú ohun gbogbo.
28 Sawar hinabow hinan God Natun babanamaim hinaya’ay ufunamaim, Jesu boro Tamah God ana fair babanamaim namare, anayabin sawar etei God bow Natun babanamaim ya, naatu God boro sawar tutufin etei ni’ukwarin ana sabuw etei isah.
29 Ní báyìí, bí kò bá sí àjíǹde, kín ní ète àwọn ènìyàn tí wọn ń tẹ bọ omi nítorí òkú? Bí àwọn òkú kò bá jíǹde rárá, nítorí kín ni a ṣe ń bamitiisi wọn nítorí wọn?
29 Naatu morobone misir maiye en na’at, sabuw iyab moroboyah efanih bapataito hibaib boro abistan hinasinaf? Naatu morobone misir maiye en na’at, aisim sabuw moroboyah efanih taih tuwah hina bapataito tebaib?
30 Nítorí kín ní àwa sì ṣe ń bẹ nínú ewu ni wákàtí gbogbo?
30 Naatu it auman aisim ata yawas takwahir tatit veya matan tayi tabowabow?
31 Mo sọ nípa ayọ̀ tí mo ní lórí yín nínú Kristi Jesu Olúwa wá pé, èmi ń kú lójoojúmọ́.
31 Taitu ayu i mar etei morob ana efanamaim ama’am. Anayabin sawar abisa Keriso kwa isa sisinaf imaim ayu kura’ara’ahu iti tur akukurerereb.
32 Kí a wí bí ènìyàn, bí mo bá ẹranko jà ní Efesu, àǹfààní kín ni ó jẹ́ fún mi? Bí àwọn òkú kò bá jíǹde,
32 Morob ufunamaim yawas men tama’am, aisim ayu iti Ephesus hai sigarafor bairi atiyow? Abisa ana gewasin boro anab? Morobone misir maiye en na’at.
33 Kí a má tàn yín jẹ́, “Ẹgbẹ́ búburú bá ìwà rere jẹ́.”
33 Men sabuw hinifufuwi a not hinakwaris. “A ofonah kakafih boro ayawas gewasin hinagurus.”
34 Ẹ jí ìjí òdodo, kí ẹ má sì dẹ́ṣẹ̀; nítorí àwọn ẹlòmíràn kò ni imọ̀ Ọlọ́run, mo sọ èyí kí ojú ba à lè tiyín.
34 Ukwar kwanabotawiy gewas, ef kakafih kwasisinaf kwanihamiyen, anayabin kwa afa God men kwaso’ob, iti ao, saise kwa biya hina’ohow.
35 Ṣùgbọ́n ẹnìkan yóò wí pé, “Báwo ni àwọn òkú yóò ṣe jíǹde? Irú ara wó ni wọn ó padà sí?”
35 Sabuw afa boro hinibatiy hinao, “Moroboyah boro mi’itube hinamisir maiye? Naatu hina mimisir biyah ana itinin boro mi’itube hinab?”
36 Ìwọ aláìmòye, ohun tí ìwọ fúnrúgbìn kì í yè bí kò ṣe pé ó ba kú,
36 Taitu, kwabikoko’aw, ub me yanamaim kutatanum boro men saife nakuboun nayenamih, baise wantoro’ot i boro namorob nare, imaibo nakuboun nayen.
37 àti èyí tí ìwọ fúnrúgbìn, kì í ṣe ara tí ń bọ̀ ni ìwọ fúnrúgbìn, ṣùgbọ́n èso lásán ni, ìbá à ṣe alikama, tàbí irú mìíràn.
37 Naatu sanabey ub o ub afa kutatanum i men biyan tutufin kwatatanumimih, baise ro’on, sanabey ro’on o ub ta ro’on.
38 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run fún ún ni ara bí o tí wù ú, àti fún olúkúlùkù irúgbìn ara tirẹ̀.
38 God ub ta’ita’imon biyah hai itinin ta ta i ana kokomaim ya, naatu ub ta’ita’imon biyah anababatun itih.
39 Gbogbo ẹran-ara kì í ṣe ẹran-ara kan náà, ṣùgbọ́n ọ̀tọ̀ ni ẹran-ara ti ènìyàn, ọ̀tọ̀ ni ẹran-ara ti ẹranko, ọ̀tọ̀ ní ti ẹja, ọ̀tọ̀ sì ní tí ẹyẹ.
39 Naatu sawar tafaramamaim biyah finimih auman hai itinin i men ta’imon, biyah i ta ta, orot babin biyah ana itinin ta, haru for biyah ana itinin ta, mamu hai itinin i ta naatu siy i hai itinin ta.
40 Ará ti òkè ọ̀run ń bẹ, ara ti ayé pẹ̀lú sì ń bẹ, ṣùgbọ́n ògo ti òkè ọ̀run ọ̀tọ̀, àti ògo ti ayé ọ̀tọ̀.
40 Naatu mar ana biyan itinin ibo ta, na’atube tafaram biyan itinin ibo ta. Baise biyat no mar nowan ana bonamanamarin itinin ibo ta, naatu biyat tafaram nowan ana bonamanamarin ibo itinin ta.
41 Ọ̀tọ̀ ni ògo ti oòrùn, ọ̀tọ̀ ni ògo ti òṣùpá, ọ̀tọ̀ sì ni ògo ti ìràwọ̀; ìràwọ̀ ṣá yàtọ̀ sí ìràwọ̀ ni ògo.
41 Veya ibo ana bonamanamarin itinin ta, sumar ibo ana bonamanamarin itinin ta, naatu daman ibo hai bonamanamarin itinin ta, baise daman wanawanahimaim ta’ita’imoh ibo hai bonamanamarin ta ta.
42 Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ sí ni àjíǹde òkú. A gbìn ín ní ìdíbàjẹ́; a sí jì í dìde ni àìdíbàjẹ́.
42 Baise Moroboyah hinamimisir maiye ana itinin i boro nati na’atube, biyat morob hubemaim tayayare ana veya biyat i emasamas, baise morobone namimisir ufunamaim boro nama wanatowan.
43 A gbìn ín ni àìní ọlá, a sí jí i dìde ni ògo; a gbìn ín ni àìlera, a sì jí í dìde ní agbára.
43 Biyat hubemaim tayayare itinin i kakafin, naatu siba’u’un, baise emimisir ana veya itinin i gewasin naatu fairin.
44 A gbìn ín ni, ara ẹran a sì jí i dìde ni ara ti ẹ̀mí.
44 Biyat tayayare i tafaram nowan, baise emimisir i mar biyan.
45 Bẹ́ẹ̀ ní a si kọ ọ́ pé, “Adamu ọkùnrin ìṣáájú, alààyè ọkàn ni a dá a”; Adamu ìkẹyìn ẹ̀mí ìsọnidààyè.
45 Buk Atamaninamaim hikirum hio na’atube, “Orot wantoro’ot wabin Adam i biyan ana yawas bai,” baise Adam bairou’abin nan i ayubit ana yawas wanatowanin baitit isan na.
46 Ṣùgbọ́n èyí tí í ṣe tí ẹ̀mí kọ ní ó kọ́kọ́ ṣáájú, bí kò ṣe èyí tí í ṣe tí ara ọkàn, lẹ́yìn náà èyí ti í ṣe ti ẹ̀mí.
46 Orot ayubit ana yawas auman ma’am i men mat na, baise orot biyat ana yawasamaim ma’am i mat na, imaibo orot ayubit ana yawasamaim ma’am na.
47 Ọkùnrin ìṣáájú ti inú erùpẹ̀ wá gẹ́gẹ́ bí ẹni erùpẹ̀: ọkùnrin èkejì láti ọ̀run wá ni.
47 Orot wantoro’ot Adam i me nowan fofobane matar, baise Adam bairou’abin i marane ra’iy.
48 Bí ẹni erùpẹ̀ ti rí, irú bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn tí í ṣe erùpẹ̀: bí ẹni tí ọ̀run ti rí, irú bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn tí í ṣe tí ọ̀run.
48 Sabuw iyab me nowan biyah i orot me’emaim ma’am biyan na’atube, sabuw iyab mar nowan biyah i orot marane rara’iy biyan na’atube.
49 Bí àwa ti rú àwòrán ẹni erùpẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni àwa ó sì rú àwòrán ẹni ti ọ̀run.
49 Tafaram orot ana ana itinin tabaib na’atube, mar ana orot nanan ana itinin boro tanab.
50 Ará, ǹjẹ́ èyí ní mo wí pé, ara àti ẹ̀jẹ̀ kò lè jogún ìjọba Ọlọ́run, bẹ́ẹ̀ ni ìdíbàjẹ́ kò lé jogún àìdíbàjẹ́.
50 Taitu, abisa ao au yabin i iti, biyat, naatu finimit men karam boro God ana aiwobomaim narun, anayabin biyat i boro namorob namas, imih men karam boro wanatowan ma’am ana efanamaim narun.
51 Kíyèsi í, ohun ìjìnlẹ̀ ni mo sọ fún un yín, gbogbo wá kì yóò sùn, ṣùgbọ́n gbogbo wá ní a ó paláradà.
51 Tain kwanarub gewas, iti tur buriburin anao kwananowar, it etei boro men tanamorobomih, baise ata itinin boro nabotabir bonamanamarin namatar
52 Lọ́gán, ni ìṣẹ́jú kan, nígbà ìpè ìkẹyìn: nítorí ìpè yóò dún, a ó sì jí àwọn òkú dìde ní àìdíbàjẹ́, a ó sì pa wá láradà.
52 tour natut ana veya namanamar ebowabow na’atube, tanimatanubamo biyat nabotabir. Anayabin tour natut ana veya murumurubih etei boro biyah fairin hinamisir, naatu biyah ana itinin boro nabotabir.
53 Nítorí pé ara ìdíbàjẹ́ yìí kò lè ṣàìgbé ìdíbàjẹ́ wọ̀, àti ara kíkú yìí kò lè ṣàìgbé ara àìkú wọ̀.
53 Biyat iti morob emasamas boro nabotabir biyat fairin wanatowan ma’ama’anin namatar.
54 Ṣùgbọ́n nígbà tí ará ìdíbàjẹ́ yìí bá ti gbé àìdíbàjẹ́ wọ̀, ti ara kíkú yìí bá sí ti gbé àìkú wọ̀ bẹ́ẹ̀ tan, nígbà náà ni ọ̀rọ̀ ti a kọ yóò ṣẹ pé, “A gbé ikú mí ní ìṣẹ́gun.”
54 Biyat iti boun tama’am boro namorob naatu namas, baise morob ufunamaim biyat boro nabotabir nan wanatowan ma’ama ana biyan nab. Imaibo Buk Atamaninamaim hikirum boro nan niturobe,
55 “Ikú, oró rẹ dà?
55 “Morob o a fair menanamaim ema’am boro inisnowah?
56 Oró ikú ni ẹ̀ṣẹ̀; àti agbára ẹ̀ṣẹ̀ ni òfin.
56 Morob ana biyababan i bowabow kakafinane ebaib, naatu bowabow kakafin ana fair i ofafaramaim ebaib.
57 Ṣùgbọ́n ọpẹ́ ní fún Ọlọ́run ẹni tí ó fì ìṣẹ́gun fún wá nípa Olúwa wá Jesu Kristi!
57 Baise God ana merar tanay anayabin Jesu Keriso, i morob ana ahay ana waf tagagir yare!
58 Nítorí náà ẹ̀yin ará mi olùfẹ́ ẹ máa dúró ṣinṣin, láìyẹsẹ̀, kí ẹ máa pọ̀ si í ní iṣẹ́ Olúwa nígbà gbogbo, ní ìwọ̀n bí ẹ̀yin ti mọ̀ pé iṣẹ́ yin kì í ṣe asán nínú Olúwa.
58 Isan imih taitu, yate nanub kwanabatkikin, mar etei Regah isan anot tutufin kwanabow, anayabin Regah isan kwabow kwabi’akir i men anayabin enamih, baise yabin auman.
Atalhos do teclado
- Capítulo anterior←
- Próximo capítulo→
- Versículo anteriork
- Próximo versículoj
- Limpar seleçãoEsc
- Esta ajuda?
Estude este capítulo no WhatsApp
Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Coríntios 15, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.