1 Coríntios 11

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR) vs AAI

Sair da comparação
AAI TUR GEWASIN O BAIBASIT BOUBUN
1 Ẹ máa tẹ̀lé àpẹẹrẹ mi, gẹ́gẹ́ bí èmi náà ti ń tẹ̀lé àpẹẹrẹ Kristi.
1 Ayu Keriso abi’u’ur na’atube kwa ayu kwani’u’uru.
2 Èmí yìn yín fún rírántí mi nínú ohun gbogbo àti fún dídi gbogbo ẹ̀kọ́ tí mo kọ́ ọ yín mú ṣinṣin gẹ́gẹ́ bí mo ṣe fi lélẹ̀ fún un yín.
2 Ayu sawar ta ta’amaim mar etei kwanunuhu isan naatu bai’obaiyen abit kwabukikin kwama’am isan, a merar ayi abobora’ara’ahi.
3 Ṣùgbọ́n mo fẹ́ kí ẹ̀yin mọ̀ pé, Kristi ni orí olúkúlùkù ọkùnrin, orí obìnrin sì ni ọkọ rẹ̀ àti orí Kristi sì ní Ọlọ́run.
3 Baise boun ayu akokok kwa etei kwanaso’ob gewas. Keriso i orot ana ukwarin, Babin ana ukwarin i orot naatu Keriso ana ukwarin i God.
4 Gbogbo ọkùnrin tó bá borí rẹ̀ nígbà tó bá ń gbàdúrà tàbí sọtẹ́lẹ̀ kò bọ̀wọ̀ fún orí rẹ̀.
4 Orot yait aribun sumasum auman eyoyoyoban, o tur God biyanane baib eo’orereb Keriso biya’ohow ebitin.
5 Bẹ́ẹ̀ náà ni obìnrin tí ó bá ń gbàdúrà tàbí tí ó bá ń sọtẹ́lẹ̀ láìbo orí rẹ̀, kò bu ọlá fún orí ara rẹ̀ nítorí ọ̀kan náà ni pẹ̀lú ẹni tí ó fárí.
5 Naatu babin yait aribun ana sumasum bosair eyoyoyoban, o tur God biyanane bai eo’orereb, aawan biya’ohow ebitin, ana itinin i babin aribun himafuribe.
6 Ṣùgbọ́n tí obìnrin bá kọ̀ láti bo orí rẹ̀, ẹ jẹ́ kí ó gé irun rẹ̀. Bí ó bá sì jẹ́ nǹkan ìtìjú fún un láti gé irun orí rẹ́, nígbà náà kí ó fi gèlè bo orí rẹ̀.
6 Babin yait aribun men nasumisum, gewasin aribun hina’afuw. Baise babin aribun afuwin o mafurin isan biyan nao’ohow na’at gewasin aribun nasum.
7 Ṣùgbọ́n ọkùnrin kò ní láti fi nǹkan bo orí rẹ́ nígbà tí ó bá ń sìn, nítorí àwòrán àti ògo Ọlọ́run ni òun í ṣe, ṣùgbọ́n ògo ọkùnrin ni obìnrin í ṣe.
7 Orot aribun men nasum, anayabin orot i God ana itinin naatu ana fair, baise babin i orot ana fair.
8 Ọkùnrin kò ti inú obìnrin wá, ṣùgbọ́n a yọ obìnrin jáde lára ọkùnrin,
8 Anayabin orot i men babinane namih, baise babin i orotone na.
9 bẹ́ẹ̀ ni a kò dá ọkùnrin fún àǹfààní obìnrin ṣùgbọ́n a da obìnrin fún ọkùnrin.
9 Na’atube orot i men babin isan God eo matar, baise babin i orot isan matar.
10 Nítorí ìdí èyí àti nítorí àwọn angẹli, ni obìnrin ṣe gbọdọ̀ ní àmì àṣẹ rẹ̀ ní orí rẹ̀.
10 Ana’anaban iti isan, tounamatar matahimaim babin aribun nasum, saise nati sumasumamaim ebi’obaiyit, babin i orot ana fair babanamaim ema’am.
11 Ẹ rántí pé, nínú ètò Ọlọ́run obìnrin kò lè wà láìsí ọkùnrin, bẹ́ẹ̀ ni ọkùnrin kò lè wà láàsí obìnrin.
11 Regah ana yawasamaim tama’am babin men orot nihamiy akisin nabin ana fairamaim nama, na’atube orot men babin nihamiy akisin nabin ana fairamaim nama.
12 Lóòtítọ́ láti ara ọkùnrin ni a ti yọ obìnrin jáde bẹ́ẹ̀ sì ni ọkùnrin tipasẹ̀ obìnrin wa. Ṣùgbọ́n láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ni ohun gbogbo ti wà.
12 Anayabin babin orotone na, na’atube babin biyanane taub orot yai. Baise sawar etei i Godane hina.
13 Kí ni ẹ̀yìn fúnra yín rò lórí ọ̀rọ̀ yìí? Ǹjẹ́ ó tọ̀nà fún obìnrin láti máa gbàdúrà Ọlọ́run ní gbangba láìbo orí rẹ̀ bí?
13 Taiyuw kwanibatiy kwana’itin, babin aribun ana sumasum nabosair, bebeyanamaim nayoyoyoban i gewasin ai en?
14 Ǹjẹ́ ìwà abínibí yín kò ha kọ́ yín pé, bí ọkùnrin bá ní irun gígùn, àbùkù ni ó jẹ́ fún un.
14 It ata so’ob i sawar biyatamaim temamatar imaim ebi’obaiyit, orot aribun ituw manin ere’er i boro biyan na’ohow.
15 Ṣùgbọ́n bí obìnrin bá ní irun gígùn, ògo ni ó jẹ́ fún un nítorí irun gígùn tí a fi fún un jẹ́ ìbòrí fún un.
15 Baise babin aribun ituw manin ere’ere i ana itinin ebigewasin. Anayabin aribun manin re’ere i yumatan ana sumasum na’atube.
16 Ṣùgbọ́n tí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ jiyàn lórí ọ̀rọ̀ yìí, ohun kan tí mo lè sọ sí gbogbo rẹ̀ ni pé, a kò ní ìlànà tí ó yàtọ̀ sí èyí tí mo ti sọ, pé obìnrin gbọdọ̀ fi gèlè bo orí rẹ̀ nígbà tí ó bá ń sọtẹ́lẹ̀ tàbí tí ó bá ń gbàdúrà láàrín ìjọ Ọlọ́run.
16 Baise orot yait ayu ao isan inagamigam, anao inanowar. Kwafiren isan ata ef men ta ema’am boro imaim tani’ufunun o God ana ekaleisia wanawanan kwafiren ana ef men ta ema’am boro i tani’a’ait.
17 Nínú àwọn àlàkalẹ̀ èmi ko ni yìn yín nítorí pé bí ẹ bá péjọ kì í ṣe fún rere bí ko ṣe fún búburú.
17 Roube’aten tur iti anao kwananowar. Ayu kwa boro men merarayow anitimih. Anayabin kwaru’ay a kou’ay kwabaib wanawanan kakafin i erara’at naatu ana gewasin i en.
18 Lọ́nà kìn-ín-ní, mo gbọ́ pe ìyapa máa ń wà láàrín yín ní ìgbà tí ẹ bá péjọpọ̀ gẹ́gẹ́ bí ìjọ, mo sì gba èyí gbọ́ dé ààyè ibìkan.
18 Ayu tur anowar kwa ekaleisia tutufin etei kwana kwabita’imon akwafiren wanawan i kouseb ema’am, naatu ayu abitumatum iti i tur anababatun.
19 Kò sí àní àní, ìyàtọ̀ gbọdọ̀ wa láàrín yín, kí àwọn tí ó ṣe ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ Ọlọ́run láàrín yín le farahàn kedere.
19 Men kwanakasiy, wanawananamaim kouseb iti na’atube emamatar, saise orot iyab sinaf gewasin tisisinaf boro bebeyan hinatit kwana’itih.
20 Nígbà tí ẹ bá pàdé láti jẹun, kì í ṣe oúnjẹ alẹ́ Olúwa ni ẹ máa ń jẹ.
20 Kwaruru’ay ana veya kwa i men Regah ana Bay Aafufun kwa’aau’umih.
21 Ṣùgbọ́n tí ara yín, nígbà tí ẹ bá fẹ́ jẹun, olúkúlùkù yín a máa sáré jẹ oúnjẹ rẹ̀ láìdúró de ẹnìkejì rẹ̀. Ebi a sì máa pa wọ́n, ẹlòmíràn wọ́n sì ń mu àmuyó àti àmupara.
21 Anayabin bay aa ana veya orot afa timatkabikabiy te’aa harew fokarih tetom tibikoko’aw, naatu sabuw afa i tibi’aamoromorob.
22 Ṣé ẹ̀yin kò ní ilé tí ẹ ti lè jẹ, tí ẹ sì ti lè mu ni? Tàbí ẹ̀yin ń gan ìjọ Ọlọ́run ni? Ẹ̀yin sì ń dójútì àwọn aláìní? Kín ni kí èmi ó wí fún un yín? Èmi yóò ha yìn yín nítorí èyí? A! Rárá o. Èmi kọ́, n kò ní yìn yín.
22 Kwa a bar tema’am boro imaim kwataa kwatatom ai en? Aisim iti na’atube kwasinaf God ana ekaleisia kwabi’afiy, naatu yababan wairafih biya’ohow kwabitih. Kwanotanot boro abisa anao kwananowar, a merar anay nati kwasisinaf isan? Boro men kafa’imo a merar anayimih.
23 Nítorí èyí tí èmi gbà lọ́wọ́ Olúwa ni mo ti fi fún un yin. Ní alẹ́ ọjọ́ tí Judasi fihàn, Olúwa Jesu Kristi mú àkàrà.
23 Anayabin ayu Regah biyanane abisa abaib i kwa ai’obaiyi. Ata Regah gugumin hiyayanuw ana maramaim rafiy bai
24 Lẹ́yìn ìgbà tí ó ti dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run fún àkàrà náà tan, ó bù ú, ó fi fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó sì wí pé, “Ẹ gbà kí ẹ sì jẹ, èyí ní ara mi tí a fi fún un yín. Ẹ máa ṣe eléyìí ni rántí mi.”
24 God ana merar yi imasib itih eo, “Iti i ayu biyau kwa abit, kwanab kwana’ani’aan ana maramaim ayu kwananuhu.”
25 Bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ lẹ́yìn oúnjẹ alẹ́, ó sì mú ago wáìnì, ó sì wí pé, “Ago yìí ni májẹ̀mú tuntun nínú ẹ̀jẹ̀ mi, ẹ máa ṣe èyí, nígbàkígbà ti ẹ̀yìn bá ń mu ú, ní ìrántí mi.”
25 Ef ta’imon kerowas isan na’atube sinaf, bay hi’aa ufunamaim kerowas wine hisuwai batabat bai, God ana merar yi, iuwih eo, “Iti kerowas i God ana Obaibasit Boubun ayu au rara’amaim ebubusuruf. Imih mar etei iti na’atube kwanasinaf, kwanatomatom ana maramaim ayu kwanuhu.”
26 Nítorí nígbàkígbà tí ẹ bá ń jẹ lára àkàrà yìí, tí ẹ sì ǹ mu nínú ago yìí, ni ẹ tún sọ nípa ikú Olúwa. Ẹ máa ṣe eléyìí títí yóò fi padà dé.
26 Mar etei iti rafiy kwana’aan, kerowasamaim wine kwanatom, naatu Regah momorob isan kwanabinan kwananan i namatabir maiye nan natit.
27 Nítorí náà tí ẹnikẹ́ni bá jẹ lára àkàrà yìí, tí ẹ sì ń mu nínú ago Olúwa yìí, ní ọ̀nà tí kò bójúmu, yóò jẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ sí ara àti ẹ̀jẹ̀ Olúwa.
27 Isan imih orot yait erebosa rafiy nab na’aan naatu Regah ana kerowasamaim natomatom, nati orot i bowabow kakafin maiyow Regah biyan naatu ana rara isan esisinaf kakaf.
28 Ìdí nìyìí tí ó fi yẹ kí ènìyàn yẹ ara rẹ̀ wò dáradára kí ó tó jẹ lára àkàrà nà án àti kí ó tó mu nínú ago náà.
28 Imih wantoro’ot orot taiyuwin ana yawas nanutitiy na’itin gewas, imaibo rafiy nab na’aan naatu kerowas nab natom.
29 Nítorí tí ẹ bá jẹ lára àkàrà, tí ẹ sì mu nínú ago láìyẹ, tí ẹ kò ronú ara Kristi àti nǹkan tí ó túmọ̀ sí, ẹ̀ ń jẹ, ẹ sì ń mú ẹ̀bi ìdájọ́ Ọlọ́run wá sórí ara yín.
29 Anayabin orot yait Regah biyan naatu ana rara hai buriburih men naso’ob gewas, rafiy nab na’aan naatu kerowasamaim wine natomatom, i taiyuwin ana baibatiyen bai enan.
30 Ìdí nìyìí tí ọ̀pọ̀ yín fi di ẹni tí kò lágbára mọ́, tí ọ̀pọ̀ yín sì ń ṣàìsàn, àwọn mìíràn nínú yín tilẹ̀ ti sùn.
30 Ana’an iti isan kwa moumur na’in biyah hiririm naatu kwabisasawuw naatu afa i himoroboka.
31 Ṣùgbọ́n tí ẹ bá yẹ ara yín wò dáradára, kí ẹ tó jẹ ẹ́, a kì yóò dá yín lẹ́jọ́.
31 Baise it taiyuwit anababatun tanabibatiyit gewas, boro men tanan God nibatiyitamih.
32 Ṣùgbọ́n nígbà tí a bá dá wa lẹ́jọ́, láti ọwọ́ Olúwa ni a ti nà wá, kí a má ba à dá wa lẹ́bi pẹ̀lú ayé.
32 Baise Regah nabibatiyit ana veya baikwatutunen boro nitit, naatu God tafaram baimakiy nabitin it boro men auman nititamih.
33 Nítorí náà, ẹ̀yin arákùnrin mi ọ̀wọ́n, nígbàkígbà ti ẹ bá péjọ láti jẹ́ oúnjẹ alẹ́ Olúwa, tàbí fún ìsìn oúnjẹ alẹ́ Olúwa, ẹ dúró de ara yín.
33 Isan imih taituwau, Regah ana Bay Aafufun isan kwanaruru’ay taituwa kwanakaifih.
34 Bí ebi bá ń pa ẹnikẹ́ni nínú yin, kí ó jẹun láti ilé wá, kí ó má ba á mú ìjìyà wá sórí ara rẹ̀ nígbà tí ẹ bá péjọ.
34 Naatu orot yait aa momorob gewasin ana baremaim bay naa, saise a kou’ay kwanabaib ana maramaim boro men God ana baibatiyen wanawanan narun. Naatu sawar afa i boro ayu anan anatitabo anayabuna.

Ler em outra tradução

Comparar com outra

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar 1 Coríntios 11, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.