Salmos 40

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Mo fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ dúró de Olúwa;

2 Ó fà mí yọ gòkè

3 Ó fi orin tuntun sí mi lẹ́nu,

4 Ayọ̀ ni fún àwọn wọ̀n-ọn-nì

5 Olúwa Ọlọ́run mi,

6 Ẹbọ àti ẹran ẹbọ ni ìwọ kò fẹ́,

7 Nígbà náà ni mo wí pé,

8 Mo ní inú dídùn

9 Èmi ti sọ ìròyìn ayọ̀ ti ìgbàlà

10 Èmi kò fi ìrànlọ́wọ́ ìgbàlà sin ní àyà mi;

11 Ìwọ má ṣe, fa àánú rẹ tí ó rọ́nú sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ mi Olúwa;

12 Nítorí pé àìníye ibi

13 Jẹ́ kí ó wù ọ́,

14 Gbogbo àwọn wọ̀n-ọn-nì ni kí ojú kí ó tì

15 Jẹ́ kí àwọn tí ó wí fún mi pé, “Háà! Háà!”

16 Jẹ́ kí gbogbo àwọn tí ń wá ọ

17 Bí ó ṣe ti èmi ni,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 40, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.