Salmos 32

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Ìbùkún ni fún àwọn

2 Ìbùkún ni fún ọkùnrin náà

3 Nígbà tí mo dákẹ́,

4 Nítorí pé ni ọ̀sán àti ní òru

5 Èmi jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi sí ọ

6 Nítorí náà jẹ́ kí gbogbo àwọn olódodo máa gbà àdúrà sí ọ

7 Ìwọ ni ibi ìpamọ́ mi;

8 Èmi yóò kọ́ ọ, èmi yóò sì fi ẹsẹ̀ rẹ lé ọ̀nà tí ìwọ yóò rìn

9 Má ṣe dàbí ẹṣin tàbí ìbáaka,

10 Ọ̀pọ̀ ìkáàánú ní yóò wà fún ènìyàn búburú,

11 Ẹ yọ̀ nínú Olúwa, kí ẹ sì ní inú dídùn, ẹ̀yìn olódodo;

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 32, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.