Salmos 19

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Àwọn ọ̀run ń sọ nípa ti ògo Ọlọ́run;

2 Wọ́n ń fọhùn ní ọjọ́ dé ọjọ́;

3 Kò sí ohùn tàbí èdè

4 Ohùn wọn jáde lọ sí gbogbo orílẹ̀ ayé,

5 Tí ó dàbí ọkọ ìyàwó tí ó ń jáde ti yàrá rẹ̀ wá,

6 Ìjáde lọ rẹ̀ ni láti òpin ọ̀run wá

7 Pípé ni òfin Olúwa,

8 Ìlànà Olúwa tọ̀nà,

9 Ìbẹ̀rù Olúwa mọ́,

10 Wọn ṣọ̀wọ́n ju wúrà lọ,

11 Nípa wọn ni a ti ṣí ìránṣẹ́ rẹ̀ létí;

12 Ta ni ó lè mọ àṣìṣe rẹ̀?

13 Wẹ ìránṣẹ́ rẹ mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ àmọ̀ọ́n-mọ̀-dá;

14 Jẹ́ kí ọ̀rọ̀ ẹnu mi àti àṣàrò ọkàn mi

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 19, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.