Salmos 150

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Ẹ fi ìyìn fún Olúwa.

2 Ẹ yìn ín fún iṣẹ́ agbára rẹ̀.

3 Ẹ fi ohùn ìpè yìn ín.

4 Ẹ fi ohun èlò orin àti ijó yìn ín

5 Ẹ yìn ín pẹ̀lú aro olóhùn òkè,

6 Jẹ́ kí gbogbo ohun tí ó ní ẹ̀mí yin Olúwa.

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 150, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.