Salmos 116

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Èmi fẹ́ràn Olúwa, nítorí ó gbọ́ ohùn mi;

2 Nítorí ó yí etí rẹ̀ padà sí mi,

3 Okùn ikú yí mi ká,

4 Nígbà náà ni mo ké pe orúkọ Olúwa:

5 Olúwa ní oore-ọ̀fẹ́, ó sì ní òdodo;

6 Olúwa pa àwọn ọlọ́kàn fífúyẹ́ mọ́

7 Padà, ìwọ ọkàn mi, sí ibi ìsinmi rẹ,

8 Nítorí ìwọ, Olúwa, ti gba ọkàn mi

9 nítorí èmi yóò máa rìn níwájú Olúwa

10 Èmi gbàgbọ́; nítorí náà mo wí pé,

11 Àti nínú ìdààmú mi mo wí pé,

12 Kí ni èmi yóò san fún Olúwa

13 Èmi yóò gbé ago ìgbàlà sókè

14 Èmi yóò mú ìlérí mi ṣẹ sí Olúwa

15 Iyebíye ní ojú Olúwa

16 Olúwa, nítòótọ́ ìránṣẹ́ rẹ ni mo jẹ́;

17 Èmi yóò rú ẹbọ ọpẹ́ sí ọ

18 Èmi yóò mú ìlérí mi sẹ sí Olúwa

19 nínú àgbàlá ilé Olúwa

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Salmos 116, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.