Miquéias 4

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Ní ọjọ́ ìkẹyìn

2 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè yóò wá,

3 Òun yóò sì ṣe ìdájọ́ láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn,

4 Ṣùgbọ́n olúkúlùkù yóò jókòó lábẹ́ àjàrà rẹ̀

5 Gbogbo àwọn ènìyàn ń rìn,

6 “Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí,

7 Èmi yóò dá àwọn arọ sí fún èyí tókù,

8 Ní ti ìwọ, ilé ìṣọ́ agbo àgùntàn,

9 Kí ni ìwọ ha ń kígbe sókè sí nísinsin yìí?

10 Máa yí síyìn-ín sọ́hùn-ún nínú ìrora,

11 Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ọ̀pọ̀lọpọ̀ Orílẹ̀-èdè kó ara wọn jọ sí ọ.

12 Ṣùgbọ́n wọn kò mọ

13 “Dìde, kí ó sì máa pa ọkà ìwọ ọmọbìnrin Sioni,

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Miquéias 4, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.