Isaías 16

Biblica® ní oore ọ̀fẹ́ láti lo Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde-Òní (YOR)

1 Fi ọ̀dọ́-àgùntàn ṣe ẹ̀bùn

2 Gẹ́gẹ́ bí alárìnkiri ẹyẹ

3 “Fún wa ní ìmọ̀ràn

4 Jẹ́ kí àwọn ìsáǹsá Moabu gbé pẹ̀lú rẹ,

5 Nínú ìfẹ́ a ó fi ìdí ìjọba kan múlẹ̀,

6 Àwa ti gbọ́ nípa ìgbéraga Moabu,

7 Nítorí náà ni àwọn ará Moabu hu,

8 Gbogbo pápá oko Heṣboni ti gbẹ,

9 Nítorí náà mo sọkún, gẹ́gẹ́ bí Jaseri ṣe sọkún,

10 Ayọ̀ àti ìdùnnú ni a ti mú kúrò

11 Ọkàn mi kérora fún Moabu gẹ́gẹ́ bí i dùùrù,

12 Nígbà tí Moabu farahàn ní ibi gíga rẹ̀,

13 Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa ti sọ nípa Moabu.

14 Ṣùgbọ́n ní àkókò yìí Olúwa wí pé, “Láàrín ọdún mẹ́ta gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀fà tí ó wà lábẹ́ ìdè ọgbà rẹ̀ ti máa kà á, ògo Moabu àti àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn rẹ̀ ni a ó kẹ́gàn, àwọn tí ó sálà nínú rẹ̀ yóò kéré níye, wọn yóò sì jẹ́ akúrẹtẹ̀.”

Ler em outra tradução

Comparar lado a lado

Estude este capítulo no WhatsApp

Peça à IA da Bíblia Fala para explicar Isaías 16, comparar traduções ou montar um estudo — tudo direto pelo WhatsApp.